Publicidade

Eclesiastes 5

Dídúró nínú ìbẹ̀Ọlọ́run

1 Ṣọ́ ìrìn rẹ nígbà o lọ ilé Ọlọ́run. ìwọ ó múra láti gbọ́ ju àti ṣe ìrúbọ aṣiwèrè, mọ̀ òun ń ṣe búburú.

2 ṣe yára pẹ̀ẹnu un rẹ,

sọ ohunkóhun níwájú Ọlọ́run.

Ọlọ́run ń bẹ ̀run

ìwọ ayé,

nítorí náà jẹ́ ̀rọ̀ rẹ mọ ìwọ̀n.

3 Gẹ́gẹ́ àlá ń , nígbà ìlépa púpọ̀ ,

bẹ́̀ ni ̀rọ̀ òmùgọ̀ nígbà ̀rọ̀ pọ̀.

4 Nígbà o ṣe ìlérí Ọlọ́run, ṣe pẹ́ mímúṣẹ, inú dídùn òmùgọ̀, ìlérí rẹ sẹ. 5 Ó sàn láti jẹ́ ̀jẹ́, ju a jẹ́ ̀jẹ́ a mu ṣẹ lọ. 6 ṣe jẹ́ ẹnu rẹ ́ sínú ̀ṣẹ̀. ṣe sọ fún òjíṣẹ́ ilé ìsìn , "Àṣìṣe ni ̀jẹ́ mi." Ọlọ́run fi le è bínú , ó ba iṣẹ́ ọwọ́ rẹ jẹ́? 7 Asán ni ̀pọ̀ àlá àti ̀rọ̀ púpọ̀. Nítorí náà dúró nínú ìbẹ̀Ọlọ́run.

Asán ni ọrọ̀ jẹ́

8 o tálákà wọ́n ń ni lára ojú púpọ̀, a ń fi òtítọ́ àti ̀tọ́ rẹ̀ ú, ṣe jẹ́ ó ́ lẹ́nu láti irú nǹkan bẹ́̀, nítorí ẹni ó ipò gíga máa ń mọ́ òṣìṣẹ́ ó lábẹ́ rẹ̀ lójú ni, síbẹ̀ àwọn kan wọ́n jẹ́ olórí àwọn méjèèjì. 9 Gbogbo wọn ni ó ń pín èrè wọ́n lórí ilẹ̀, àní ọba pàápàá ń jẹ èrè lórí oko.

10 Ẹni ó ìfẹ́ owó í owó ànító,

ẹni ó ìfẹ́ ọrọ̀ í ìtẹ́lọ́rùn

pẹ̀èrè ó ń wọlé fún un.

11 ẹrù ti ń pọ̀ i,

náà ni àwọn ó ń jẹ ́ yóò máa pọ̀ i

Èrè e ni wọ́n jẹ́ ẹni ó ni nǹkan ṣe ,

ó máa inú ara rẹ dùn nípa wọn?

12 Oorun alágbàṣe a máa dùn,

yálà ó jẹun kékeré ni tàbí ó jẹun púpọ̀,

ṣùgbọ́n ̀pọ̀ ̀rọ̀ ọlọ́rọ̀

í jẹ́ ó sùn rárá.

13 Mo ti ohun ó burú gidigidi lábẹ́ oòrùn

ọrọ̀ a pamọ́ fún ìparun ẹni ni nǹkan.

14 Tàbí ọrọ̀ ó sọnù nípa àìrí ojúrere,

nítorí ó ọmọkùnrin

ohun yóò fi sílẹ̀ fún un.

15 Ìhòhò ni ènìyàn láti inú ìyá rẹ̀,

ó ṣe , bẹ́̀ ni yóò kúrò

ohunkóhun nínú iṣẹ́ rẹ̀

ó le ọwọ́ rẹ̀.

16 Ohun búburú gbá à ni eléyìí pàápàá.

ènìyàn ṣe , ni yóò lọ

ni èrè ó jẹ

nígbà ó ṣe wàhálà fún afẹ́fẹ́?

17 Ó ń jẹ nínú òkùnkùn gbogbo ọjọ́ rẹ̀,

pẹ̀iyè ríra ó ga, ìnira àti ìbínú.

18 Nígbà náà ni mo i dájú , ó dára, ó tọ̀fún ènìyàn láti jẹ, ó mu, ó ìtẹ́lọ́rùn nínú iṣẹ́ wàhálà rẹ̀ lábẹ́ oòrùn, àkókò ọjọ́ ayé díẹ̀ Ọlọ́run ti fi fún un, nítorí ìpín rẹ̀ ni èyí. 19 Síwájú , nígbà Ọlọ́run fún ẹnikẹ́ni ọrọ̀ àti ohun ìní, ó fún un lágbára láti gbádùn wọn, láti gba ìpín rẹ̀ inú rẹ̀ dùn iṣẹ́ rẹ̀bùn Ọlọ́run ni èyí. 20 Ó máa ń ronú lẹ́̀kọ̀̀kan nípa ọjọ́ ayé rẹ lẹ́̀kọ̀̀kan nítorí Ọlọ́run ń pa á mọ́ pẹ̀inú dídùn ọkàn rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-