Publicidade

Gálatas 2

Àwọn aposteli tẹ́wọ́ gba Paulu

1 2.1: Ap 15.2. Lẹ́yìn ọdún mẹ́rìnlá, ni mo tún gòkè lọ Jerusalẹmu pẹ̀Barnaba, mo Titu lọ pẹ̀mi. 2 Mo gòkè lọ nípa ohun ti a fihàn mi, mo fi ìyìnrere náà mo ń wàásù láàrín àwọn aláìkọlà àwọn ó jẹ́ ẹni ńlá nínú wọn, èyí i ìkọ̀kọ̀, èmi ó ba á sáré, tàbí ó máa ba à jẹ́ mo ti sáré lásán. 3 Ṣùgbọ́n a fi agbára Titu ó pẹ̀mi, ẹni í ṣe ara Giriki láti kọlà. 4 ̀rọ̀ yìí wáyé nítorí àwọn èké arákùnrin wọn yọ́ wọ inú àárín wa láti yọ́ òmìnira wa , èyí àwa ni nínú Kristi Jesu, wọn wa sínú ìdè. 5 2.5: Ap 15.23-29.Àwọn ẹni ti a fún ni àǹfààní láti gbọ́ ̀rọ̀ wọn fún ìṣẹ́kan; ̀yin o máa tẹ̀síwájú nínú òtítọ́ ìyìnrere náà.

6 2.6: De 10.17. Ṣùgbọ́n ti àwọn ó dàbí ẹni pàtàkìohunkóhun ó wọn jásí, jẹ́ nǹkan kan fún mi; Ọlọ́run fi ẹnikẹ́ni ṣe ṣe ìdájọ́ rẹ̀—àwọn ènìyàn yìí fi ohunkóhun kún ̀rọ̀ mi. 7 Ṣùgbọ́n kàkà bẹ́̀, nígbà wọn i a fi ìyìnrere àwọn aláìkọlà le mi lọ́wọ́, a fi ìyìnrere àwọn onílà Peteru lọ́wọ́. 8 Nítorí Ọlọ́run, ẹni ó ṣiṣẹ́ nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ Peteru gẹ́gẹ́ aposteli àwọn Júù, òun kan náà ni ó ṣiṣẹ́ nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ mi gẹ́gẹ́ aposteli àwọn aláìkọlà. 9 Jakọbu, Peteru, àti Johanu, àwọn ẹni ó dàbí ̀wọ́n, fún èmi àti Barnaba ni ọwọ́ ̀tún ìdàpọ̀ nígbà wọ́n oore-ọ̀fẹ́ a fi fún mi, wọ́n gbà àwa náà tọ àwọn aláìkọlà lọ, nígbà ti àwọn náà lọ sọ́dọ̀ àwọn Júù. 10 Ohun gbogbo wọ́n béèrè fún ni , a máa rántí àwọn tálákà, ohun kan náà gan an mo ń làkàkà láti ṣe.

Paulu tako Peteru

11 2.11: Ap 11.19-26. Ṣùgbọ́n nígbà Peteru Antioku, mo takò ó lójú ara rẹ̀, nítorí ó jẹ̀bi, mo a . 12 Nítorí àwọn kan ó ti ̀dọ̀ Jakọbu , ó ti ń ba àwọn aláìkọlà jẹun; ṣùgbọ́n nígbà wọ́n , ó fàsẹ́yìn, ó ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ kúrò lọ́dọ̀ àwọn aláìkọlà nítorí ó bẹ̀àwọn ti ó kọlà. 13 Àwọn Júù ó pawọ́pọ̀ pẹ̀rẹ̀ láti jùmọ̀ ṣe àgàbàgebè, bẹ́̀ wọn fi àgàbàgebè wọn si Barnaba lọ́.

14 Nígbà mo i wọn rìn déédé gẹ́gẹ́ òtítọ́ ìyìnrere, mo fún Peteru níwájú gbogbo wọn , "ìwọ, ì ṣe Júù ba ń rìn gẹ́gẹ́ ìwà àwọn kèfèrí, èéṣe ìwọ fi ń fi agbára mu àwọn kèfèrí láti máa rìn àwọn Júù?

15 "Àwa i ṣe Júù nípa ìbí, i ì ṣe aláìkọlà ẹlẹ́ṣẹ̀, 16 2.16: Sm 143.2; Ro 3.20.a mọ̀ a ẹnikẹ́ni láre nípa iṣẹ́ òfin, ṣe nípa ìgbàgbọ́ nínú Jesu Kristi, àní àwa pẹ̀gbà Jesu Kristi gbọ́, a a wa láre nípa ìgbàgbọ́ Kristi, í i ṣe nípa iṣẹ́ òfin, nítorí nípa iṣẹ́ òfin ènìyàn kan a ó láre.

17 "Ṣùgbọ́n nígbà àwa ń ̀láti ìdáláre nípa Kristi, ó di ̀àwa pẹ̀jẹ́ ẹlẹ́ṣẹ̀, ǹjẹ́ èyí ha jásí Kristi ń ṣe ìránṣẹ́ ̀ṣẹ̀ ? a ì! 18 Nítorí mo tún gbé àwọn ohun mo palẹ̀ , mo fi ara mi hàn arúfin.

19 "Nítorí nípa òfin, mo di òkú òfin, èmi láààyè Ọlọ́run. 20 2.20: Ga 1.4.A ti kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀Kristi, èmí láààyè mọ́, ṣùgbọ́n Kristi ń gbé inú mi wíwà mo láààyè nínú ara, mo láààyè nínú ìgbàgbọ́ Ọmọ Ọlọ́run, ẹni o fẹ́ mi, ó fi òun tìkára rẹ̀ fún mi. 21 Èmi ya oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run apá kan, nítorí a le ti ipasẹ̀ òfin jèrè òdodo, a jẹ́ Kristi lásán."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-