Publicidade

Hebreus 1

Ọmọ o ṣe pàtàkì fún àwọn Angẹli

1 ìgbà àtijọ́, Ọlọ́run àwọn baba ńlá wa sọ̀rọ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì ̀pọ̀ ìgbà àti onírúurú ̀, 2 ṣùgbọ́n ìgbà ìkẹyìn yìí Ọlọ́run ń wa sọ̀rọ̀ nípasẹ̀ Ọmọ rẹ̀ Jesu Kristi, ẹni ó fi ṣe ajogún ohun gbogbo, nípasẹ̀ ẹni ó gbogbo ayé yìí àti ohun gbogbo ń bẹ nínú rẹ̀. 3 Ọmọ í ṣe ìtànṣán ògo Ọlọ́run àti àwòrán òun tìkára rẹ̀, ó ń fi ̀rọ̀ agbára rẹ̀ ohun gbogbo dúró. Lẹ́yìn ó ti ṣe ìwẹ̀̀ṣẹ̀ wa tan, ó jókòó ọwọ́ ̀tún Ọláńlá òkè. 4 Nítorí náà, ó ti fi bẹ́̀ di ẹni ó ga ipò ju angẹli lọ, ó ti jogún orúkọ èyí ó tayọ̀ tiwọn.

5 Nítorí ̀kan nínú àwọn angẹli Ọlọ́run fi ìgbà kan sọ fún :

"Ìwọ ni ọmọ mi;

lónìí ni mo "?

Àti pẹ̀,

"Èmi yóò jẹ́ baba fún un,

Òun yóò jẹ́ ọmọ mi"?

6 Àti pẹ̀, nígbà Ọlọ́run rán àkọ́rẹ̀ si ayé wa yìí. Ó pàṣẹ ,

"jẹ́ gbogbo àwọn angẹli Ọlọ́run foríbalẹ̀ fún un."

7 Àti nípa ti àwọn angẹli, ó ,

"Ẹni ó àwọn angẹli rẹ̀ ̀,

àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ọwọ́ iná."

8 Ṣùgbọ́n ó sọ nípa Ọmọ rẹ̀ ,

"Ìtẹ́ rẹ, Ọlọ́run, láé àti láéláé ni,

̀aládé òdodo ni ̀ìjọba rẹ.

9 Ìwọ fẹ́ òdodo, bẹ́̀ ni ìwọ kórìíra iṣẹ́ búburú;

nítorí èyí ni Ọlọ́run, àní Ọlọ́run rẹ ṣe fi àmì òróró ayọ̀ yàn

ó gbé ju àwọn ẹgbẹ́ rẹ lọ."

10 Ó tún sọ ,

"àtètèkọ́ṣe, ìwọ Olúwa, ìwọ fi ìdí ayé sọlẹ̀,

àwọn ̀run jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ ara rẹ.

11 Wọn yóò ṣègbé, ṣùgbọ́n ìwọ yóò síbẹ̀

gbogbo wọn ni yóò di àkísà ̀.

12 kíká ni ìwọ yóò wọn aṣọ,

ìpààrọ̀ aṣọ ni a ó pààrọ̀ wọn.

Ṣùgbọ́n ìwọ fúnra rẹ̀ yóò yípadà

àti ọdún rẹ yóò òpin."

13 Èwo nínú àwọn angẹli a gbọ́ Ọlọ́run fi ìgbà kan fún ,

"Jókòó ọwọ́ ̀tún mi

títí èmi yóò fi sọ àwọn ̀rẹ

di àpótí ìtìsẹ̀ rẹ"?

14 í ha á ṣe ̀ń jíṣẹ́ ni àwọn angẹli í ṣe ; a rán lọ síta láti máa ṣiṣẹ́ fún àwọn yóò jogún ìgbàlà?

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-