Pular para o conteúdo
Publicidade

Heberu 11

24 11.24: Ek 2.10,11-15. Nípa ìgbàgbọ́ ni Mose, nígbà o dàgbà, ó kọ̀ ki a máa òun ni ọmọ ọmọbìnrin Farao; 25 o kúkú yàn láti máa ba àwọn ènìyàn Ọlọ́run jìyà, ju jíjẹ fàájì ̀ṣẹ̀ fún ìgbà díẹ̀. 26 Ó ka ̀gàn Kristi si ọrọ̀ ó pọ̀àwọn ìṣúra Ejibiti lọ, nítorí ó ń wo èrè náà.

Veja também