Publicidade

Hebreus 4

Ìsinmi fún àwọn ènìyàn Ọlọ́run

1 Nítorí náà, gẹ́gẹ́ Ọlọ́run ti ṣe ìlérí àtiwọ inú ìsinmi rẹ̀ fún wa, jẹ́ á bẹ̀, ẹnikẹ́ni nínú yín ba à dàbí ẹni ó kùnà rẹ̀. 2 Nítorí àwa gbọ́ ìwàásù ìyìnrere, gẹ́gẹ́ a ti wàásù rẹ̀ fún àwọn náà pẹ̀, ṣùgbọ́n ̀rọ̀ wọ́n gbọ́ ṣe wọ́n àǹfààní, nítorí dàpọ̀ mọ́ ìgbàgbọ́ nínú àwọn ó gbọ́ . 3 Nítorí àwa ó ti gbàgbọ́ wọ inú ìsinmi gẹ́gẹ́ ó ,

"mo búra nínú ìbínú mi,

Wọn yóò wọ inú ìsinmi mi.’ "

ó tilẹ̀ jẹ́ a parí iṣẹ́ wọ̀nyí láti ìpìlẹ̀ ayé. 4 Nítorí ó ti sọ níbìkan ti ọjọ́ keje báyìí , "Ọlọ́run sinmi ọjọ́ keje kúrò nínú iṣẹ́ rẹ̀ gbogbo." 5 Àti níhìn-ín yìí pẹ̀ó , "Wọn yóò wọ inú ìsinmi mi."

6 Nítorí náà ó jẹ́ , ó ku àwọn kan wọ inú rẹ̀, àti àwọn a ti wàásù ìyìnrere náà fún ìṣáájú wọ inú rẹ̀ nítorí àìgbọ́ràn. 7 Àti , ó yan ọjọ́ kan, ó nínú ìwé Dafidi , "Lónìí," lẹ́yìn ìgbà pípẹ́ bẹ́̀; a níṣàájú,

"Lónìí ̀yin gbọ́ ohùn rẹ̀,

ṣe ọkàn yín le."

8 Nítorí, ìbá ṣe Joṣua fún wọn ìsinmi, òun sọ̀rọ̀ nípa ọjọ́ ìsinmi mìíràn lẹ́yìn náà, 9 nítorí náà ìsinmi kan fún àwọn ènìyàn Ọlọ́run. 10 Nítorí ẹni ó ba bọ́ sínú ìsinmi rẹ̀, òun pẹ̀sinmi kúrò nínú iṣẹ́ tirẹ̀, gẹ́gẹ́ Ọlọ́run ti sinmi kúrò nínú iṣẹ́ tirẹ̀. 11 Nítorí náà, jẹ́ á múra gírí láti wọ inú ìsinmi náà, ẹnikẹ́ni ba à ṣubú nípa irú àìgbàgbọ́ kan náà.

12 Nítorí ̀rọ̀ Ọlọ́run , ó agbára, ó mu ju idàkídà olójú méjì lọ, ó ń gún ni, àní títí pínpín ọkàn àti ̀, àti oríkèé àti ̀inú egungun, òun ni olùmọ̀ èrò inú àti ète ọkàn. 13 ̀kan farahàn níwájú rẹ̀, ṣùgbọ́n ohun gbogbo ni ó níhòhò a ṣípáyà fún ojú rẹ̀, níwájú ẹni àwa yóò jíyìn.

Jesu ni olórí àlùfáà tòótọ́

14 Ǹjẹ́ a ti olórí àlùfáà ńlá kan, ó ti la àwọn ̀run kọjá lọ, Jesu Ọmọ Ọlọ́run, jẹ́ a di ìjẹ́wọ́ wa ṣinṣin. 15 Nítorí a olórí àlùfáà ṣàì ba ni kẹ́dùn nínú àìlera wa, ẹni a ti dánwò lọ́gbogbo gẹ́gẹ́ àwa, ṣùgbọ́n òun dẹ́ṣẹ̀. 16 Nítorí náà, jẹ́ a si ibi ìtẹ́ oore-ọ̀fẹ́ pẹ̀ìgboyà, a àánú gbà, a oore-ọ̀fẹ́ láti máa ran ni lọ́wọ́ àkókò ó wọ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-