Publicidade

Hebreus 8

Olórí àlùfáà ti májẹ̀tuntun

1 Nísinsin yìí, kókó ohun à ń sọ nìyí. Àwa irú olórí àlùfáà bẹ́̀, ó jókòó lọ́wọ́ ̀tún ìtẹ́ Ọláńlá nínú àwọn ̀run, 2 Ìránṣẹ́ ibi mímọ́, àti ti àgọ́ tòótọ́, Olúwa pa, í ṣe ènìyàn.

3 Nítorí a fi olórí àlùfáà kọ̀̀kan jẹ láti máa ̀bùn láti máa ẹbọ, nítorí náà ó ṣe pàtàkì fún eléyìí náà láti nǹkan ó máa fi sílẹ̀. 4 ó jẹ́ ó ayé ni, òun ti jẹ́ àlùfáà, nítorí àwọn ọkùnrin ó ń fi ̀bùn sílẹ̀ ti òfin ṣe á sílẹ̀. 5 Àwọn ẹni ń jọ́sìn nínú pẹpẹ kan ó jẹ́ àpẹẹrẹ àti òjìji ohun ń bẹ ̀run. Ìdí abájọ nìyí a fi kìlọ̀ fún Mose nígbà ó fẹ́ kọ́ àgọ́, nítorí ó , "Kíyèsí i, ìwọ ó ṣe wọ́n gẹ́gẹ́ àpẹẹrẹ wọn, ti a fi hàn ́ ni orí òkè." 6 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí o ti gba iṣẹ́ ìránṣẹ́ ó ni ọlá , níwọ̀n o ti jẹ alárinà májẹ̀o dára i ṣe, èyí a fi ṣe òfin lórí ìlérí o sàn bẹ́̀ lọ.

7 Nítorí ìbá ṣe májẹ̀ìṣáájú àbùkù, ǹjẹ́ a ti ààyè fún èkejì. 8 Nítorí ó àbùkù lára wọn, ó ,

"Ìgbà kan ń bọ̀, ni Olúwa ,

Èmi yóò ilé Israẹli

àti ilé Juda májẹ̀tuntun.

9 í ṣe gẹ́gẹ́ májẹ̀

mo ti àwọn baba baba wọn ,

nígbà mo wọ́n lọ́wọ́ láti wọn jáde

kúrò ilẹ̀ Ejibiti, nítorí wọn jẹ́ olóòtítọ́ májẹ̀mi

èmi ta wọ́n nu, ni Olúwa .

10 Nítorí èyí ni májẹ̀èmi yóò ilé Israẹli

lẹ́yìn àwọn ọjọ́ wọ̀nyí, ni Olúwa .

Èmi ó fi òfin mi inú wọn,

èmi ó kọ wọ́n ọkàn wọn,

èmi ó máa jẹ́ Ọlọ́run fún wọn,

wọn ó máa jẹ́ ènìyàn fún mi.

11 Olúkúlùkù tún máa kọ́ ara ìlú rẹ̀,

tàbí olúkúlùkù arákùnrin rẹ̀, , Mọ Olúwa,

nítorí gbogbo wọn ni yóò mọ̀ ,

láti kékeré àgbà.

12 Nítorí èmi ó ṣàánú fún àìṣòdodo wọn,

àti ̀ṣẹ̀ wọn àti àìṣedéédéé wọn lèmi ki yóò rántí mọ́."

13 èyí ó , májẹ̀títún ó ti sọ ti ìṣáájú di ti láéláé. Ṣùgbọ́n èyí ó ń di i ti láéláé ó ń gbó, o múra àti di asán.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-