Publicidade

João 12

A fi àmì òróró yàn Jesu ni Betani

1 Nítorí náà, nígbà àjọ ìrékọjá ku ọjọ́ mẹ́, Jesu Betani, níbi Lasaru , ẹni ó ti , Jesu dìde kúrò nínú òkú. 2 Wọ́n ṣe àsè alẹ́ fún un níbẹ̀. Marta ń ṣe ìránṣẹ́, ṣùgbọ́n Lasaru jẹ́ ̀kan nínú àwọn ó jókòó níbi tábìlì rẹ̀. 3 Nígbà náà ni Maria òróró ìkunra nadi, òsùwọ̀n lita kan, àìlábùlà, olówó iyebíye, ó ń fi kun Jesu ẹsẹ̀, ó ń fi irun orí rẹ̀ nu ẹsẹ̀ rẹ̀ . Ilé kún fún òórùn ìkunra náà.

4 Nígbà náà ni ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Judasi Iskariotu, ọmọ Simoni ẹni yóò fi í hàn, , 5 "Èéṣe a ta òróró ìkunra yìí ̀́dúnrún owó idẹ a fi fún àwọn tálákà?" 6 Ṣùgbọ́n ó èyí, í ṣe nítorí ó náání àwọn tálákà; ṣùgbọ́n nítorí ó jẹ́ olè, òun ni ó ni àpò, a máa ohun a fi sínú rẹ̀ láti fi ran ara rẹ lọ́wọ́.

7 Nígbà náà ni Jesu , "fi í sílẹ̀, ó ṣe é sílẹ̀ de ọjọ́ ìsìnkú mi. 8 Nígbà gbogbo ni ̀yin à tálákà pẹ̀yín; ṣùgbọ́n èmi ni nígbà gbogbo."

9 Nítorí náà, ìjọ ènìyàn nínú àwọn Júù ni ó mọ̀ ó níbẹ̀; wọ́n , í ṣe nítorí Jesu nìkan, ṣùgbọ́n wọn Lasaru pẹ̀, ẹni ó ti dìde kúrò nínú òkú. 10 Ṣùgbọ́n àwọn olórí àlùfáà gbìmọ̀ wọn pa Lasaru pẹ̀, 11 nítorí nípasẹ̀ rẹ̀ ni ̀pọ̀ nínú àwọn Júù jáde lọ, wọ́n gbà Jesu gbọ́.

Jesu gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọ Jerusalẹmu

12 ọjọ́ kejì nígbà ̀pọ̀ ènìyàn ó àjọ gbọ́ , Jesu ń bọ̀ Jerusalẹmu. 13 Wọ́n imọ̀ ̀pẹ, wọ́n jáde lọ pàdé rẹ̀, wọ́n ń kígbe ,

"Hosana!"

"Olùbùkún ni ẹni ń bọ̀ orúkọ Olúwa!"

"Olùbùkún ni ọba Israẹli!"

14 Nígbà Jesu ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan, ó gùn ún; gẹ́gẹ́ a ti kọ̀,

15 "bẹ̀, ọmọbìnrin Sioni;

ó, ọba rẹ ń bọ̀ ,

o jókòó lórí ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́."

16 Nǹkan wọ̀nyí tètè àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ṣùgbọ́n nígbà a ṣe Jesu lógo, nígbà náà ni wọ́n rántí , a kọ̀nǹkan wọ̀nyí nípa rẹ̀ i.

17 Nítorí náà, ìjọ ènìyàn ó lọ́dọ̀ rẹ̀ nígbà o Lasaru jáde nínú ibojì rẹ̀, ó i dìde kúrò nínú òkú, jẹ́rìí i. 18 Nítorí èyí ni ìjọ ènìyàn ṣe lọ pàdé rẹ̀, nítorí wọ́n gbọ́ ó ti ṣe iṣẹ́ àmì yìí. 19 Nítorí náà àwọn Farisi fún ara wọn , "kíyèsi ti borí ohunkóhun? wo gbogbo ayé ti ń wọ́ tọ̀ ́!"

Jesu sọ nípa ikú rẹ̀

20 Àwọn Giriki kan nínú àwọn ó gòkè láti sìn nígbà àjọ, 21 Àwọn wọ̀nyí ni ó tọ Filipi , ẹni í ṣe ará Betisaida Galili, wọ́n ń béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, , "Alàgbà, àwa ń fẹ́ Jesu!" 22 Filipi , ó sọ fún Anderu; Anderu àti Filipi , wọ́n sọ fún Jesu.

23 Jesu wọn lóhùn , "Wákàtí náà , a ó ṣe Ọmọ Ènìyàn lógo. 24 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo fún yín, ṣe alikama bọ́ ilẹ̀, ó , ó òun nìkan; ṣùgbọ́n ó , yóò so ̀pọ̀lọpọ̀ èso. 25 Ẹni ó fẹ́ ̀rẹ̀ yóò sọ ́ ; ẹni ó kórìíra ̀rẹ̀ láyé yìí ni yóò pa á mọ́ títí ó fi di ìyè àìnípẹ̀kun. 26 ẹnikẹ́ni ń sìn , ó máa tọ̀ lẹ́yìn, àti pe níbi èmi , níbẹ̀ ni ìránṣẹ́ mi yóò pẹ̀, ẹnikẹ́ni ń sìn , òun ni Baba yóò bu ọlá fún.

27 "ìsinsin yìí ni a ń pọ́n ọkàn mi lójú; kín ni èmi ó ? Baba, gbà kúrò nínú wákàtí yìí? Rárá, ṣùgbọ́n nítorí èyí ni mo ṣe wákàtí yìí. 28 Baba, ṣe orúkọ rẹ lógo!"

Nígbà náà ni ohùn kan ti ̀run , , "Èmi ti ṣe é lógo!" 29 Nítorí náà ìjọ ènìyàn ó dúró níbẹ̀, wọ́n gbọ́ , , "Àrá ń sán." Àwọn ẹlòmíràn , "Angẹli kan ni ó ń a sọ̀rọ̀."

30 Jesu dáhùn , "í ṣe nítorí mi ni ohùn yìí ṣe , ṣe nítorí yín. 31 ìsinsin yìí ni ìdájọ́ ayé yìí : nísinsin yìí ni a ó aládé ayé yìí jáde. 32 Àti èmi, a gbé mi sókè kúrò ayé, èmi ó fa gbogbo ènìyàn sọ́dọ̀ ara mi!" 33 Ṣùgbọ́n ó èyí, ó ń ṣe àpẹẹrẹ irú ikú òun yóò .

34 Nítorí náà àwọn ìjọ ènìyàn a lóhùn , "Àwa gbọ́ nínú òfin , Kristi títí láéláé, ìwọ ha ṣe , A ó gbé Ọmọ Ènìyàn sókè? Ta ni ó ń jẹ́ Ọmọ Ènìyàn yìí?"

35 Nígbà náà ni Jesu fún wọn , "Nígbà díẹ̀ i ni ìmọ́lẹ̀ láàrín yín, máa rìn nígbà ̀yin ìmọ́lẹ̀, òkùnkùn ṣe yín, ẹni ó ń rìn òkùnkùn mọ ibi òun ń lọ. 36 Nígbà ̀yin ìmọ́lẹ̀, gba ìmọ́lẹ̀ gbọ́, jẹ́ ọmọ ìmọ́lẹ̀!" Nǹkan wọ̀nyí ni Jesu sọ, ó jáde lọ, ó fi ara pamọ́ fún wọn.

Àwọn Júù n tẹ̀síwájú nínú àìgbàgbọ́

37 Ṣùgbọ́n ó ti ṣe ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì báyìí lójú wọn, wọn gbà á gbọ́. 38 ̀rọ̀ wòlíì Isaiah ṣẹ, èyí ó sọ ,

"Olúwa, ta ni ó gba ìwàásù wa gbọ́

Àti ta ni a fi apá Olúwa hàn fún?"

39 Nítorí èyí ni wọn fi gbàgbọ́, nítorí Isaiah tún sọ ,

40 "Ó ti fọ́ wọn lójú,

Ó ti àyà wọn le;

wọn ba à fi ojú wọn ,

wọn ba à fi ọkàn wọn mọ̀,

wọn ba à yípadà, èmi ba à wọn láradá."

41 Nǹkan wọ̀nyí ni Isaiah , nítorí ó ti ògo rẹ̀, ó sọ̀rọ̀ rẹ̀.

42 Síbẹ̀ ̀pọ̀ nínú àwọn olórí gbà á gbọ́ pẹ̀; ṣùgbọ́n nítorí àwọn Farisi wọn jẹ́wọ́ rẹ̀, a ba à yọ wọ́n kúrò nínú Sinagọgu, 43 nítorí wọ́n fẹ́ ìyìn ènìyàn ju ìyìn ti Ọlọ́run lọ.

44 Jesu kígbe ó , "Ẹni ó gbà gbọ́, èmi kọ́ ni ó gbàgbọ́ ṣùgbọ́n ẹni ó rán mi. 45 Ẹni ó mi, ó ẹni ó rán mi. 46 Èmi ni ìmọ́lẹ̀ ó ayé, ẹnikẹ́ni ó gbà gbọ́ ṣe nínú òkùnkùn.

47 "ẹnikẹ́ni gbọ́ ̀rọ̀ mi, pa wọ́n mọ́, èmi yóò ṣe ìdájọ́ rẹ̀ nítorí èmi láti ṣe ìdájọ́ ayé, ṣe láti gba ayé . 48 Ẹni ó kọ̀ , gba ̀rọ̀ mi, ó ẹnìkan ń ṣe ìdájọ́ rẹ̀; ̀rọ̀ mo ti sọ, òun náà ni yóò ṣe ìdájọ́ rẹ̀ ọjọ́ ìkẹyìn. 49 Nítorí èmi ̀rọ̀ sọ fún ara mi, ṣùgbọ́n Baba ó rán mi, ni ó ti fún mi àṣẹ, ohun èmi ó sọ, àti èyí èmi ó . 50 Èmi mọ̀ ìyè àìnípẹ̀kun ni òfin rẹ̀, nítorí náà, àwọn ohun mo , gẹ́gẹ́ Baba ti sọ fún mi, bẹ́̀ ni mo !"

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-