Pular para o conteúdo
Publicidade

Lucas 1

Ìsọtẹ́lẹ̀ ibi Jesu

26 oṣù kẹfà Ọlọ́run rán angẹli Gabrieli ìlú kan Galili, à ń Nasareti, 27 wúńdíá kan a ṣèlérí láti fẹ́ fún ọkùnrin kan, a ń Josẹfu, ti ìdílé Dafidi; orúkọ wúńdíá náà a máa jẹ́ Maria. 28 Angẹli náà tọ̀ ́ , ó , "Àlàáfíà fun , ìwọ ẹni a kọjú ṣe oore, Olúwa ń bẹ pẹ̀rẹ."

29 Ṣùgbọ́n ọkàn Maria lélẹ̀ nítorí ̀rọ̀ náà, ó nínú ara rẹ̀ , irú kíkí kín ni èyí. 30 1.30: Lk 1.13.Ṣùgbọ́n angẹli náà fún un , "bẹ̀, Maria, nítorí ìwọ ti ojúrere lọ́dọ̀ Ọlọ́run. 31 1.31: Lk 2.21; Mt 1.21.Ìwọ yóò lóyún nínú rẹ, ìwọ ó ọmọkùnrin kan, ìwọ ó pe orúkọ rẹ̀ Jesu. 32 Òun ó pọ̀, ọmọ ̀gá-ògo jùlọ ni a ó máa é, Olúwa Ọlọ́run yóò fi ìtẹ́ Dafidi baba rẹ̀ fún. 33 1.33: Mt 28.18; Da 2.44.Yóò jẹ ọba lórí ilé Jakọbu títí láé; ìjọba rẹ̀ yóò ìpẹ̀kun."

34 1.34: Lk 1.18. Nígbà náà ni Maria béèrè lọ́wọ́ angẹli náà , "Èyí yóò ha ti ṣe bẹ́̀, nígbà èmi ì mọ ọkùnrin."

35 1.35: Mt 1.20. Angẹli náà dáhùn ó fún un , "̀Mímọ́ yóò tọ̀ ́ , agbára ̀gá-ògo jùlọ yóò síji ́. Nítorí náà ohun mímọ́ a ó ti inú rẹ , Ọmọ Ọlọ́run ni a ó máa é. 36 kíyèsi i, Elisabeti ìbátan rẹ náà yóò ọmọkùnrin kan ògbólógbòó rẹ̀, èyí ni oṣù kẹfà fún ẹni à ń àgàn. 37 1.37: Gẹ 18.14.Nítorí ohun Ọlọ́run le ṣe."

38 Maria dáhùn , "ó ọmọ ̀dọ̀ Olúwa; ó fún mi gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ." Angẹli náà fi í sílẹ̀ lọ.

Veja também