Pular para o conteúdo
Publicidade

Lucas 1

Orin Sakariah

67 Sekariah baba rẹ̀ kún fún ̀Mímọ́, ó sọtẹ́lẹ̀, ó :

68 "Olùbùkún ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli;

nítorí ó ti bojú , ó ti àwọn ènìyàn rẹ̀ nídè,

69 Ó ti gbé ìwo ìgbàlà sókè fún wa

ilé Dafidi ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀;

70 (ó ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì rẹ̀ mímọ́ tipẹ́tipẹ́),

71 , a ó gbà lọ́wọ́

àwọn ̀wa àti lọ́wọ́ àwọn ó kórìíra .

72 Láti ṣe àánú ó ṣèlérí fún àwọn baba wa,

àti láti rántí májẹ̀rẹ̀ mímọ́,

73 ìbúra ó ti fún Abrahamu baba wa,

74 láti gbà lọ́wọ́ àwọn ̀wa,

àwa ó máa sìn láìfòyà,

75 ni ìwà mímọ́ àti òdodo níwájú rẹ̀, ọjọ́ ayé wa gbogbo.

76 1.76: Lk 7.26; Ml 4.5. "Àti ìwọ, ọmọ mi, wòlíì ̀gá-ògo jùlọ ni a ó máa ́:

nítorí ìwọ ni yóò ṣáájú Olúwa láti tún ̀rẹ̀ ṣe;

77 1.77: Mk 1.4. láti fi ìmọ̀ ìgbàlà fún àwọn ènìyàn rẹ̀

fún ìmúkúrò ̀ṣẹ̀ wọn,

78 1.78: Ml 4.2; Ef 5.14. nítorí ìyọ́Ọlọ́run ;

nípa èyí ìlà-oòrùn láti òkè bojú ,

79 1.79: Isa 9.2; Mt 4.16. Láti fi ìmọ́lẹ̀ fún àwọn ó jókòó

òkùnkùn àti òjìji ikú,

àti láti fi ẹsẹ̀ wa ̀àlàáfíà."

Veja também