Pular para o conteúdo
Publicidade

Lucas 12

15 12.15: 1Tm 6.6-10.Ó fún wọn , "Kíyèsára o máa ṣọ́ra nítorí ojúkòkòrò: nítorí ìgbésí ayé ènìyàn dúró ̀pọ̀ ohun ó ."

16 Ó pa òwe kan fún wọn , "Ilẹ̀ ọkùnrin ọlọ́rọ̀ so ̀pọ̀lọpọ̀ èso. 17 Ó nínú ara rẹ̀ , Èmi ó ti ṣe, nítorí èmi ibi èmi ó gbé èso mi jọ .

18 "Ó , Èyí ni èmi ó ṣe: èmi ó àká mi palẹ̀, èmi ó kọ́ èyí ó tóbi; níbẹ̀ ni èmi ó gbé to gbogbo èso àti ọrọ̀ mi jọ . 19 Èmi ó fún ọkàn mi , ọkàn, ìwọ ọrọ̀ púpọ̀ a jọ fún ̀pọ̀ ọdún; sinmi, máa jẹ, máa mu, máa yọ̀.’

20 12.20: Jr 17.11; Jb 27.8; Sm 39.6; Lk 12.33-34. "Ṣùgbọ́n Ọlọ́run fún un , Ìwọ aṣiwèrè, lóru yìí ni a ó béèrè ọkàn rẹ lọ́wọ́ rẹ; ǹjẹ́ ti ta ni nǹkan wọ̀nyí yóò ha ṣe, ìwọ ti pèsè sílẹ̀?’

21 "Bẹ́̀ ni ẹni ó to ìṣúra jọ fún ara rẹ̀, ọrọ̀ lọ́dọ̀ Ọlọ́run."

Veja também