Publicidade

Lucas 13

ronúpìwàdà á ṣègbé

1 Àwọn kan àkókò náà ó sọ ti àwọn ará Galili fún un, ̀jẹ̀ ẹni Pilatu dàpọ̀ mọ́ ẹbọ wọn. 2 13.2: Jh 9.1-3.Jesu dáhùn ó fún wọn , "̀yin ṣe àwọn ará Galili wọ̀nyí ṣe ẹlẹ́ṣẹ̀ ju gbogbo àwọn ará Galili lọ, nítorí wọ́n jẹ irú ìyà bá-wọ̀n-ọn-nì? 3 Mo fún yín, ṣe ̀yin pẹ̀ronúpìwàdà, gbogbo yín ni yóò ṣègbé bẹ́̀ gẹ́gẹ́. 4 Tàbí àwọn méjìdínlógún, ilé ìṣọ́ Siloamu , ó pa wọ́n, ̀yin ṣe wọ́n ṣe ẹlẹ́ṣẹ̀ ju gbogbo àwọn ènìyàn ń bẹ Jerusalẹmu lọ? 5 Mo fún yín, ṣe ̀yin ronúpìwàdà, gbogbo yín ni yóò ṣègbé bẹ́̀ gẹ́gẹ́."

6 13.6-9: Mt 21.18-20; Mk 11.12-14,20-21. Ó pa òwe yìí fún wọn , "Ọkùnrin kan igi ̀pọ̀tọ́ kan a gbìn ọgbà àjàrà rẹ̀; ó , ó ń èso lórí rẹ̀, nǹkan. 7 13.7: Mt 3.10; 7.19; Lk 3.9.Ó fún olùṣọ́gbà rẹ̀ , à ó, láti ọdún mẹ́ta ni èmi ti ń í wo èso lórí igi ̀pọ̀tọ́ yìí, èmi nǹkan: e lulẹ̀; èéṣe ó fi ń gbilẹ̀ lásán pẹ̀?

8 "Ó dáhùn ó fún un , Olúwa, jọ̀wọ́ rẹ̀ ọdún yìí pẹ̀, títí èmi ó fi tu ilẹ̀ ìdí rẹ̀ yíká, títí èmi ó fi bu ìlẹ̀i. 9 ó so èso, o dara bẹ́̀: so, ǹjẹ́ lẹ́yìn èyí ìwọ ó e lulẹ̀.’ "

A obìnrin arọ láradá ọjọ́ ìsinmi

10 Ó ń kọ́ni nínú Sinagọgu kan ọjọ́ ìsinmi. 11 kíyèsi i, obìnrin kan níbẹ̀ ó ̀àìlera, láti ọdún méjìdínlógún , ẹni ó tẹ̀ tán, le gbé ara rẹ̀ sókè ó ti ó ṣe. 12 Nígbà Jesu i, ó é ̀dọ̀, ó fún un , "Obìnrin yìí, a sílẹ̀ lọ́wọ́ àìlera rẹ." 13 Ó fi ọwọ́ rẹ̀ e, Lójúkan náà a ti sọ ́ di títọ́, ó ń yin Ọlọ́run lógo.

14 13.14: Ek 20.9-10; Lk 6.6-11; 14.1-6; Jh 5.1-18. Olórí Sinagọgu kún fún ìrunú, nítorí Jesu ni láradá ọjọ́ ìsinmi, ó fún ìjọ ènìyàn , ọjọ́ mẹ́ń bẹ a fi í ṣiṣẹ́, nínú wọn ni ̀yin ó á ṣe dídá ara yín, ó ṣe ọjọ́ ìsinmi.

15 13.15: Lk 7.13; 14.5; Mt 12.11. Nígbà náà ni Olúwa dáhùn, ó fún un , "̀yin àgàbàgebè, olúkúlùkù yín í màlúù tàbí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ kúrò ibùso, í í á lọ mu omi ọjọ́ ìsinmi. 16 13.16: Lk 19.9.yẹ a obìnrin yìí í ṣe ọmọbìnrin Abrahamu sílẹ̀ ìdè yìí ọjọ́ ìsinmi, ẹni Satani ti , à ó láti ọdún méjìdínlógún yìí ?"

17 Nígbà ó nǹkan wọ̀nyí, ojú ti gbogbo àwọn ̀rẹ̀, gbogbo ìjọ ènìyàn yọ̀ fún ohun ìyanu gbogbo ó ṣe.

Òwe irúgbìn kéré jùlọ àti ohun n ìyẹ̀fun

18 13.18-19: Mt 13.31-32; Mk 4.30-32. Ó , "Kín ni ìjọba Ọlọ́run jọ? Kín ni èmi ó fiwé? 19 Ó dàbí hóró musitadi, ọkùnrin kan , ó sọ sínú ọgbà rẹ̀; ó , ó di igi ńlá; àwọn ẹyẹ ojú ̀run ń gbé orí ̀ka rẹ̀."

20 13.20-21: Mt 13.33. Ó tún , "Kín ni èmi ìbá fi ìjọba Ọlọ́run ? 21 Ó dàbí ìwúkàrà, obìnrin kan , ó fi sínú òsùwọ̀n ìyẹ̀fun mẹ́ta, títí gbogbo rẹ̀ ó fi di wíwú."

̀tóóró

22 13.22: Lk 9.51; 17.11; 18.31; 19.11. Ó ń la àárín ìlú àti ìletò lọ, ó ń kọ́ni, ó ń rìn lọ Jerusalẹmu. 23 13.23-24: Mt 7.13-14; Jh 10.7.Ẹnìkan bi í , Olúwa, díẹ̀ ha kọ ni àwọn a ó gbàlà?

Ó fún wọn , 24 "làkàkà láti gba ojú ̀tóóró wọlé, nítorí mo fún yín, ènìyàn púpọ̀ ni yóò ̀láti wọ̀ ́, wọn yóò wọlé. 25 13.25: Mt 25.10-12.Nígbà baálé ilé dìde lẹ́̀kan fùú, ó ti ìlẹ̀kùn, ̀yin ó bẹ̀rẹ̀ í dúró lóde, ó máa kan ìlẹ̀kùn, , Olúwa, Olúwa, ṣí i fún wa!

"Òun ó dáhùn fún yín , Èmi mọ̀ ibi ̀yin ti .Bẹ́̀ ni èmi mọ̀ yín.

26 13.26-27: Mt 7.21-23; 25.41; Lk 6.46. "Nígbà náà ni ̀yin ó bẹ̀rẹ̀ , Àwa ti jẹ, àwa ti mu níwájú rẹ, ìwọ kọ́ni ìgboro ìlú wa.

27 "Òun ó , Èmi fún yín èmi mọ̀ ibi ̀yin ti ; lọ kúrò lọ́dọ̀ mi gbogbo ̀yin ń ṣiṣẹ́ ̀ṣẹ̀.’

28 13.28-29: Mt 8.11-12. "Níbẹ̀ ni ẹkún àti ìpayínkeke yóò , nígbà ̀yin ó Abrahamu, àti Isaaki, àti Jakọbu, àti gbogbo àwọn wòlíì, ìjọba Ọlọ́run, a ó ti ̀yin sóde. 29 Wọn ó ti ilẹ̀ ìlà-oòrùn, àti ìwọ̀-oòrùn , àti láti àríwá, àti gúúsù , wọn ó jókòó ìjọba Ọlọ́run. 30 13.30: Mt 19.30; Mk 10.31.ó, àwọn ẹni ̀yìn ń bẹ yóò di ẹni iwájú, àwọn ẹni iwájú ń bẹ yóò di ẹni ̀yìn."

Jesu káàánú fún Jerusalẹmu

31 wákàtí kan náà, díẹ̀ nínú àwọn Farisi tọ̀ ́ , wọ́n fún un , "Jáde, ìwọ lọ kúrò níhìn-ín yìí: nítorí Herodu ń fẹ́ pa ́."

32 13.32: Hb 2.10; 7.28. Ó fún wọn , "lọ, ̀yin sọ fún kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ náà , Kíyèsi i, èmi ń àwọn ̀èṣù jáde, èmi ń ṣe ìmúláradá lónìí àti lọ́la, àti ọjọ́ mẹ́ta èmi ó ṣe àṣepé. 33 Ṣùgbọ́n èmi jẹ́ rìn lónìí, àti lọ́la, àti ̀túnla: dájúdájú wòlíì kan ki yóò ṣègbé lẹ́yìn odi Jerusalẹmu.

34 13.34-35: Mt 23.37-39; Lk 19.41. "Jerusalẹmu, Jerusalẹmu, ìwọ o pa àwọn wòlíì, o sọ òkúta lu àwọn a rán pa; nígbà mélòó ni èmi ń fẹ́ ràgà bo àwọn ọmọ rẹ, àgbébọ̀ adìyẹ ti í ràgà bo àwọn ọmọ rẹ̀ lábẹ́ apá rẹ̀, ṣùgbọ́n ̀yin fẹ́! 35 13.35: Jr 22.5; Sm 118.26; Lk 19.38.ó, a fi ilé yín sílẹ̀ fún yín ahoro. Lóòtítọ́ ni mo fún yín, ̀yin yóò mi títí yóò fi di àkókò ̀yin ó , Olùbùkún ni ẹni ó ń bọ̀ orúkọ Olúwa.’ "

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-