Publicidade

Lucas 16

Òwe ọlọ́gbọ́n òṣìṣẹ́

1 Ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pẹ̀, "Ọkùnrin ọlọ́rọ̀ kan , ó ìríjú kan; òun náà ni wọ́n fi sùn ún , ó ti ń fi ohun ìní rẹ̀ ṣòfò. 2 Nígbà ó é, ó fún un , Èéṣe èmi fi ń gbọ́ èyí ? Ṣírò iṣẹ́ ìríjú rẹ; nítorí ìwọ ṣe ìríjú mi mọ́.’

3 "Ìríjú náà nínú ara rẹ̀ , Èwo ni èmi ó ṣe? Nítorí olúwa mi gba iṣẹ́ ìríjú lọ́wọ́ mi: èmi le ṣiṣẹ́ oko, bẹ́̀ ni ojú ń láti ṣagbe. 4 Mo mọ èyí èmi yóò ṣe, nígbà a mi kúrò níbi iṣẹ́ ìríjú, àwọn ènìyàn le gbà sínú ilé wọn.

5 "Ó pe àwọn ajigbèsè olúwa rẹ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀, ó fún èkínní , Èló ni ìwọ jẹ olúwa mi?

6 "Ó , ̀́dẹ́gbẹ̀rún (900) òsùwọ̀n òróró.

"Ó fún un , ìwé rẹ, jókòó nísinsin yìí, o kọ àádọ́ta irinwó (450).

7 "Nígbà náà ni ó bi ẹnìkejì , Èló ni ìwọ jẹ?

"Òun , Ẹgbẹ̀rún (1,000) òsùwọ̀n alikama.

"Ó fún un , ìwé rẹ, o kọ ẹgbẹ̀rin (800).

8 "Olúwa rẹ̀ yin aláìṣòótọ́ ìríjú náà, nítorí ó fi ọgbọ́n ṣe é, àwọn ọmọ ayé yìí à gbọ́n ìran wọn ju àwọn ọmọ ìmọ́lẹ̀ lọ. 9 Èmi fún yín, fi ọrọ̀ ayé yìí yan ̀rẹ́ fún ara yín , nígbà o ba lọ, wọn ó le gbà yín ibùjókòó wọn títí ayé.

10 "Ẹni ó ṣe olóòtítọ́ nínú ohun kínkínní, ó ṣe olóòtítọ́ púpọ̀ pẹ̀: ẹni ó ṣe aláìṣòótọ́ ohun kínkínní, ó ṣe aláìṣòótọ́ ohun púpọ̀ pẹ̀. 11 Ǹjẹ́ ̀yin ti jẹ́ olóòtítọ́ nínú ọrọ̀ ayé yìí, ta ni yóò fi ̀rọ̀ tòótọ́ fún yín? 12 ̀yin ti jẹ́ olóòtítọ́ nínú ohun í ṣe ti ẹlòmíràn, ta ni yóò fún yín ohun í ṣe ti ̀yin tìkára yín?

13 "í ẹnìkan ó sin ̀méjì. Òun yóò kórìíra ̀kan yóò fẹ́ràn èkejì, tàbí ó fi ara mọ́ ̀kan ó yan èkejì ìpọ̀. ̀yin sin Ọlọ́run àti owó papọ̀."

14 Àwọn Farisi, wọ́n ojúkòkòrò gbọ́ gbogbo nǹkan wọ̀nyí, wọ́n yọ ṣùtì i. 15 Ó fún wọn , "̀yin ni àwọn ń àre fún ara yín níwájú ènìyàn; ṣùgbọ́n Ọlọ́run mọ ọkàn yín, nítorí ohun ti a gbéga lójú ènìyàn, ìríra ni níwájú Ọlọ́run.

Àfikún àwọn ̀kọ́

16 "Òfin àti àwọn wòlíì ń bẹ títí di ìgbà Johanu, Láti ìgbà náà ni a ti ń wàásù ìròyìn ayọ̀ ìjọba Ọlọ́run, olúkúlùkù ń fi ipá wọ inú rẹ̀. 17 Ṣùgbọ́n ó rọrùn fún ̀run òun ayé láti kọjá lọ, ju èyí ó kéré nínú òfin ó yẹ.

18 "Ẹnikẹ́ni ó kọ aya rẹ̀ sílẹ̀, ó gbé ẹlòmíràn ìyàwó, ó ṣe panṣágà: ẹnikẹ́ni ó gbé, ẹni ọkọ rẹ̀ kọ̀sílẹ̀ ìyàwó náà, ó ṣe panṣágà.

Ọlọ́rọ̀ kan àti Lasaru

19 "Ǹjẹ́ ọkùnrin ọlọ́rọ̀ kan , ó ń wọ aṣọ elése àlùkò àti aṣọ àlà dáradára, a máa jẹ dídùndídùn lójoojúmọ́. 20 Alágbe kan à ń Lasaru, wọ́n máa ń gbé kalẹ̀ lẹ́bàá ̀ilé rẹ̀, ó kún fún ooju, 21 Òun a máa fẹ́ a fi èérún ó ti orí tábìlì ọlọ́rọ̀ bọ́ sílẹ̀ bọ́ òun, àwọn ajá , wọ́n a ooju .

22 "Ó ṣe, alágbe , a ti ọwọ́ àwọn angẹli gbé e lọ oókan àyà Abrahamu: ọlọ́rọ̀ náà pẹ̀, a sin ín; 23 ipò òkú ni ó gbé ojú rẹ̀ sókè, ó ń bẹ nínú ìjìyà oró, ó Abrahamu òkèrè, àti Lasaru oókan àyà rẹ̀. 24 Ó , ó , Baba Abrahamu, ṣàánú fún mi, o rán Lasaru, ó tẹ orí ìka rẹ̀ bọ omi, ó fi ahọ́n; nítorí èmi ń joró nínú ̀wọ́n iná yìí.

25 "Ṣùgbọ́n Abrahamu , Ọmọ, rántí , nígbà ayé rẹ, ìwọ ti gba ohun rere tìrẹ, àti Lasaru ohun búburú, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ara rọ̀ ́, ìwọ ń joró. 26 Àti pẹ̀gbogbo èyí, a gbé ̀gbun ńlá kan agbede-méjì àwa àti ̀yin, àwọn ń fẹ́ ba á le rékọjá láti ìhín lọ sọ́dọ̀ yín, ẹnikẹ́ni le ti ̀hún rékọjá tọ̀ .

27 "Ó , Ǹjẹ́ mo bẹ̀ ́, baba, ìwọ ó rán Lasaru lọ ilé baba mi, 28 nítorí mo arákùnrin márùn-ún; ó fún wọn àwọn ó ba á ibi oró yìí pẹ̀.

29 "Abrahamu fún un , Wọ́n Mose àti àwọn wòlíì; wọn ó gbọ́ tiwọn.

30 "Ó , Bẹ́̀ kọ́, Abrahamu baba; ṣùgbọ́n ẹnìkan ti inú òkú tọ̀ wọ́n lọ, wọn ó ronúpìwàdà.

31 "Ó fún un , wọn gbọ́ ti Mose àti ti àwọn wòlíì, a yóò wọn ọkàn padà ẹnìkan tilẹ̀ ti inú òkú dìde.’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-