Publicidade

Lucas 21

Oore opó

1 Nígbà ó gbé ojú sókè, ó àwọn ọlọ́rọ̀ ń fi ̀bùn wọn sínú àpótí ìṣúra. 2 Ó tálákà opó kan pẹ̀, ó ń sọ owó idẹ wẹ́wẹ́ méjì síbẹ̀. 3 Ó , "Lóòótọ́ ni mo fún yín, tálákà opó yìí fi i ju gbogbo wọn lọ, 4 nítorí gbogbo àwọn wọ̀nyí fi sínú ̀bùn Ọlọ́run láti ̀pọ̀lọpọ̀ ìní wọn; ṣùgbọ́n òun nínú àìní rẹ̀ ó sọ gbogbo ohun ìní rẹ̀ ó sínú rẹ̀."

Àwọn àmì ìkẹyìn ayé

5 àwọn kan ti ń sọ̀rọ̀ nípa tẹmpili, a ti fi òkúta dáradára àti ̀bùn ṣe é ̀ṣọ́, fun Ọlọ́run, Jesu 6 "Ohun ̀yin ń wọ̀nyí, ọjọ́ ń bọ̀, nígbà a yóò fi òkúta kan sílẹ̀ lórí èkejì a yóò lulẹ̀."

7 Wọ́n béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, , "Olùkọ́, nígbà wo ni nǹkan wọ̀nyí yóò bẹ́̀? Àti àmì kín ni yóò , nígbà nǹkan wọ̀nyí yóò fi ṣẹ?"

8 Ó , "máa kíyèsára, a à yín ṣìnà: nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ yóò orúkọ mi, yóò máa , Èmi Kristi náà àkókò náà dẹ̀dẹ̀.’ ṣe tọ̀ wọ́n lẹ́yìn. 9 Ṣùgbọ́n nígbà ̀yin gbúròó ogun àti ìdágìrì, ṣe fòyà; nítorí nǹkan wọ̀nyí láti kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀, ṣùgbọ́n òpin náà í ṣe lójúkan náà."

10 Nígbà náà ni ó fún wọn , "Orílẹ̀-èdè yóò dìde orílẹ̀-èdè, àti ìjọba ìjọba. 11 Ilẹ̀-rírì ńlá yóò káàkiri, àti ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn; ohun ̀, àti àmì ńlá yóò ti ̀run .

12 "Ṣùgbọ́n ṣáájú gbogbo nǹkan wọ̀nyí, wọn ó nawọ́ yín, wọn ó ṣe inúnibíni yín, wọn ó yín lọ Sinagọgu, àti sínú túbú, wọn ó yín lọ sọ́dọ̀ àwọn ọba àti àwọn ìjòyè nítorí orúkọ mi. 13 o si jẹ́rìí nípa mi. 14 Nítorí náà pinnu rẹ̀ ọkàn yín ko ronú ṣáájú, ó ti dáhùn. 15 Nítorí èmi ó fún yín ẹnu àti ọgbọ́n, gbogbo àwọn ̀yín yóò sọ̀rọ̀-òdì , wọn yóò lójú. 16 A ó fi yín hàn láti ọwọ́ àwọn òbí yín , àti àwọn arákùnrin, àti àwọn ìbátan, àti àwọn ̀rẹ́; òun ó a pa nínú yín. 17 A ó kórìíra yín lọ́dọ̀ gbogbo ènìyàn nítorí orúkọ mi. 18 Ṣùgbọ́n irun orí yín kan yóò ṣègbé. 19 Nínú ìdúró ṣinṣin yín ni ̀yin ó jèrè ọkàn yín.

20 "Nígbà ̀yin ti a fi ogun Jerusalẹmu , mọ̀ nígbà náà , ìsọdahoro rẹ̀ dẹ̀dẹ̀. 21 Nígbà náà ni àwọn ń bẹ Judea sálọ sórí òkè; àti àwọn ń bẹ láàrín rẹ̀ wọn jáde kúrò; àwọn ó ń bọ̀ ìgbèríko ṣe wọ inú rẹ̀ . 22 Nítorí ọjọ́ ̀san ni ọjọ́ wọ̀nyí, a ohun gbogbo a ti kọ̀rẹ̀ ṣẹ. 23 Ṣùgbọ́n ègbé ni fún àwọn ó lóyún, àti àwọn ó fi ọyàn fún ọmọ mu ọjọ́ wọ̀nyí! Nítorí ìpọ́njú púpọ̀ yóò lórí ilẹ̀ àti ìbínú àwọn ènìyàn wọ̀nyí. 24 Wọn ó ti ojú idà ṣubú, a ó dìwọ́n ìgbèkùn lọ orílẹ̀-èdè gbogbo; Jerusalẹmu yóò di ìtẹ̀mọ́lẹ̀ lẹ́sẹ̀ àwọn aláìkọlà, títí àkókò àwọn aláìkọlà yóò fi kún.

25 "Àmì yóò oorun, àti òṣùpá, àti ìràwọ̀; àti lórí ilẹ̀ ayé ìdààmú fún àwọn orílẹ̀-èdè nínú ìpayà híhó Òkun àti ìgbì omi. 26 Àyà àwọn ènìyàn yóò máa fún ìbẹ̀, àti ìrètí nǹkan wọ̀nyí ń bọ̀ sórí ayé: nítorí àwọn agbára ̀run ni a ó tìtì. 27 Nígbà náà ni wọn ó Ọmọ Ènìyàn yóò máa bọ̀ nínú àwọsánmọ̀ pẹ̀agbára àti ògo ńlá. 28 Ṣùgbọ́n nígbà nǹkan wọ̀nyí bẹ̀rẹ̀ í ṣẹ, ǹjẹ́ wo òkè, gbé orí yín sókè; nítorí ìdáǹdè yín dẹ̀dẹ̀."

29 Ó pa òwe kan fún wọn , "kíyèsi igi ̀pọ̀tọ́, àti gbogbo igi. 30 Nígbà wọ́n rúwé, ̀yin i, mọ̀ fúnra ara yín , ìgbà ̀̀rùn fẹ́́rẹ́. 31 Gẹ́gẹ́ bẹ́̀ náà ni ̀yin, nígbà ̀yin nǹkan wọ̀nyí o ṣẹ, ̀yin mọ̀ , ìjọba Ọlọ́run dẹ̀dẹ̀.

32 "Lóòótọ́ ni mo fún yín, ìran yìí yóò rékọjá, títí gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò fi ṣẹ. 33 ̀run àti ayé yóò rékọjá, ṣùgbọ́n ̀rọ̀ mi yóò rékọjá.

34 "Ṣùgbọ́n máa kíyèsára yín, ọkàn yín ṣe kún fún wọ̀bìà, àti fún ọtí àmupara, àti fún àníyàn ayé yìí, ọjọ́ náà yóò fi yín lójijì ìkẹ́kùn. 35 Nítorí bẹ́̀ ni yóò gbogbo àwọn ń gbé orí gbogbo ilẹ̀ ayé. 36 Ǹjẹ́ máa ṣọ́, máa gbàdúrà nígbà gbogbo, ba à la gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹlẹ̀, dúró níwájú Ọmọ Ènìyàn."

37 Lọ́sàn án, Jesu a máa kọ́ni tẹmpili, lóru, a máa jáde lọ í wọ̀ òkè à ń Òkè Olifi. 38 Gbogbo ènìyàn ń tọ̀ ́ tẹmpili kùtùkùtù òwúrọ̀, láti gbọ́rọ̀ rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-