Pular para o conteúdo
Publicidade

Lucas 7

Ìgbàgbọ́ ̀gágun Romu kan

1 7.1-10: Mt 8.5-10,13; Jh 4.46-53. Nígbà ó parí gbogbo ̀rọ̀ rẹ̀ fun àwọn ènìyàn, ó wọ Kapernaumu lọ. 2 Ọmọ ̀dọ̀ balógun ̀rún kan, ó ṣọ̀wọ́n fún un, ṣàìsàn, ó ń lọ. 3 Nígbà ó gbúròó Jesu, ó rán àwọn àgbàgbà Júù i, ó ń bẹ̀ ́ ó ọmọ ̀dọ̀ òun láradá. 4 Nígbà wọ́n ̀dọ̀ Jesu, wọ́n fi ìtara bẹ̀ ́, , "Ó yẹ ẹni òun ìbá ṣe èyí fún. 5 7.5: Ap 10.2.Nítorí ó fẹ́ràn orílẹ̀-èdè wa, ó ti kọ́ Sinagọgu kan fún wa." 6 Jesu ń wọn lọ.

Nígbà jìn etí ilé mọ́, balógun ̀rún náà rán àwọn ̀rẹ́ i, , "Olúwa, ṣe yọ ara rẹ lẹ́nu, nítorí èmi yẹ ìwọ ìbá fi wọ abẹ́ òrùlé mi. 7 Nítorí náà èmi èmi náà yẹ láti tọ̀ ́ , ṣùgbọ́n sọ gbólóhùn kan, a ó ọmọ ̀dọ̀ mi láradá. 8 Nítorí èmi náà pẹ̀jẹ́ ẹni a fi abẹ́ àṣẹ, ó ọmọ-ogun lẹ́yìn mi, mo fún ̀kan , Lọ,a lọ; àti fún òmíràn , ,a ; àti fún ọmọ ̀dọ̀ mi , Ṣe èyí,a ṣe é."

9 Nígbà Jesu gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, ẹnu , ó yípadà ìjọ ènìyàn ń tọ̀ ́ lẹ́yìn, ó , "Mo fún yín èmi irú ìgbàgbọ́ ńlá èyí nínú àwọn ènìyàn Israẹli." 10 Nígbà àwọn oníṣẹ́ padà ilé, wọ́n ọmọ ̀dọ̀ náà ń ṣàìsàn, ara rẹ̀ ti .

Veja também