Publicidade

Lamentações 3

1 Èmi ni ọkùnrin ó ìpọ́njú

pẹ̀̀ìbínú rẹ.

2 Ó ti mi jáde ó mi rìn

nínú òkùnkùn ju ti ìmọ́lẹ̀.

3 Nítòótọ́, ó ti ọwọ́ rẹ̀ padà mi

síwájú àti síwájú i gbogbo ọjọ́.

4 Ó jẹ́ àwọ̀ mi àti ẹran-ara mi gbó

ó tún ṣẹ́ egungun mi.

5 Ó ti fi ìgbèkùn, ó ti mi

pẹ̀ìkorò àti làálàá.

6 Ó mi gbé nínú òkùnkùn,

ti àwọn ti fún ìgbà pípẹ́.

7 Ó ti mọ́ ilé, nítorí náà n le è sálọ;

ó ti fi ̀wọ̀n mi mọ́lẹ̀.

8 Pàápàá nígbà mo fún ìrànlọ́wọ́,

ó kọ àdúrà mi.

9 Ó fi ògiri òkúta ̀mi;

ó ̀mi wọ́.

10 i beari ó dùbúlẹ̀,

i kìnnìún ó pamọ́.

11 Ó wọ́ mi kúrò ̀, ó tẹ̀ mọ́lẹ̀

ó fi mi sílẹ̀ láìsí ìrànlọ́wọ́.

12 Ó fa ọfà rẹ̀ yọ

ó fi ṣe ohun ìtafàsí.

13 Ó fa ọkàn ya

pẹ̀ọfà nínú àkọ̀ rẹ̀.

14 Mo di ẹni yẹ̀yẹ́ láàrín àwọn ènìyàn mi;

wọn yẹ̀yẹ́ mi pẹ̀orin gbogbo ọjọ́.

15 Ó ti kún mi pẹ̀ewé kíkorò

àti ìdààmú omi.

16 Ó ti fi òkúta kán eyín mi;

ó ti tẹ̀ mọ́lẹ̀ nínú eruku.

17 Mo ti jìnnà àlàáfíà;

mo ti gbàgbé ohun àṣeyege ń ṣe.

18 Nítorí náà mo , "Ògo mi ti lọ

àti ìrètí mi nínú Olúwa."

19 Mo ṣe ìrántí ìpọ́njú àti ìdààmú mi,

ìkorò àti ìbànújẹ́.

20 Mo ṣèrántí wọn,

ọkàn mi gbọgbẹ́ nínú mi.

21 Síbẹ̀, èyí ni mo ọkàn

àti nítorí náà mo nírètí.

22 Nítorí ìfẹ́ Olúwa ó lágbára ni àwa fi ṣègbé,

nítorí ti àánú rẹ í kùnà.

23 Wọ́n jẹ́ ̀tún àárọ̀;

títóbi ni òdodo rẹ̀.

24 Mo fún ara mi, ìpín mi ni Olúwa;

nítorí náà èmi yóò dúró ́.

25 Dídára ni Olúwa fún àwọn ó ìrètí nínú rẹ̀,

àwọn ó ń a.

26 Ó dára a sùúrù

fún ìgbàlà Olúwa.

27 Ó dára fún ènìyàn láti gbé àjàgà

nígbà ó èwe.

28 Jẹ́ ó jókòó ìdákẹ́ jẹ́́,

nítorí Olúwa ti fi fún un.

29 Jẹ́ ó bo ojú rẹ̀ sínú eruku

ìrètí .

30 Jẹ́ ó fi ̀rẹ̀kẹ́ fún àwọn yóò gbá a,

jẹ́ ó ìdójútì.

31 Ènìyàn di ìtanù

lọ́dọ̀ Olúwa títí láé.

32 Lóòtítọ́ ó ìbànújẹ́ , yóò fi àánú hàn,

nítorí títóbi ni ìfẹ́ rẹ̀.

33 Nítorí mọ̀ ́n mọ̀ ìpọ́njú

tàbí ìrora fún ọmọ ènìyàn.

34 Láti tẹ mọ́lẹ̀ lábẹ́ ẹsẹ̀

gbogbo àwọn ẹlẹ́wọ̀n ilẹ̀ náà.

35 Láti ṣẹ́ ọmọ ènìyàn fún ̀tọ́ rẹ̀

níwájú ̀gá-ògo jùlọ,

36 láti ìdájọ́ ènìyàn padà,

ǹjẹ́ Olúwa ohun bẹ́̀.

37 Ta ni yóò sọ̀rọ̀ yóò bẹ́̀

Olúwa fi àṣẹ i.

38 Ǹjẹ́ í ṣe láti ẹnu ̀gá-ògo jùlọ

ni rere àti búburú ń ?

39 ̀alààyè ṣe ń kùn

nígbà ó ń jìyà ̀ṣẹ̀ rẹ̀?

40 jẹ́ a yẹ ̀wa, a dán an ,

a tọ Olúwa lọ.

41 jẹ́ a gbé ọkàn àti ọwọ́ wa sókè

Ọlọ́run ̀run, a ,

42 "Àwa ti ṣẹ̀ a ti ṣọ̀tẹ̀

ìwọ fi ̀ṣẹ̀ wa .

43 "Ìwọ fi ìbínú bo ara rẹ ìwọ ń lépa wa;

ìwọ ń parun láìsí àánú.

44 Ìwọ ti fi àwọsánmọ̀ bo ara rẹ

àdúrà wa ba à ̀dọ̀ rẹ.

45 Ó ti sọ di èérí àti ààtàn

láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo.

46 "Gbogbo àwọn ̀wa ti la ẹnu wọn

gbòòrò wa.

47 Àwa ti jìyà àti ìparun,

nínú ìbẹ̀àti ewu."

48 Omijé ń sàn ojú mi odò

nítorí a pa àwọn ènìyàn mi run.

49 Ojú mi fún omijé,

láì sinmi,

50 títí ìgbà Olúwa yóò síjú wolẹ̀

láti òkè ̀run yóò i.

51 Ohun mo ìbẹ̀ọkàn mi

nítorí gbogbo àwọn obìnrin ìlú mi.

52 Àwọn ó jẹ́ ̀mi láìnídìí

dẹ ẹyẹ.

53 Wọ́n gbìyànjú láti òpin ayé mi nínú ihò

wọ́n ju òkúta .

54 Orí mi kún fún omi,

mo ìgbẹ̀yìn .

55 Mo pe orúkọ rẹ, Olúwa,

láti ̀gbun ìsàlẹ̀ ihò.

56 Ìwọ gbọ́ ̀bẹ̀ mi, "ṣe di etí rẹ

igbe ̀bẹ̀ mi fún ìtura."

57 O tòsí nígbà mo ́,

o , "ṣe bẹ̀."

58 Olúwa, ìwọ gba ẹjọ́ mi ,

o ra ̀mi padà.

59 O ti i, Olúwa, búburú a ṣe mi.

Gba ẹjọ́ mi !

60 Ìwọ ti ̀gbun ̀san wọn,

gbogbo ìmọ̀ wọn mi.

61 Olúwa ìwọ ti gbọ́ ̀gàn wọn

àti ìmọ̀ búburú wọn mi,

62 ohun àwọn ̀mi ń sọ

mi gbogbo ọjọ́.

63 wọ́n! jíjòkòó tàbí dídìde,

wọ́n ń ṣẹlẹ́mi nínú orin wọn.

64 Olúwa san wọ́n lẹ́san ohun ó tọ́ wọn

fún ohun ọwọ́ wọn ti ṣe.

65 Fi ìbòjú wọ́n ọkàn,

o fi wọ́n .

66 Ni wọ́n lára o pa wọ́n run pẹ̀ìbínú,

lábẹ́ ̀run Olúwa.

Veja também

Publicidade
Lamentações
Ver todos os capítulos de Lamentações
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-