Publicidade

Lamentações 4

1 Báwo ni wúrà ṣe sọ ògo dídán rẹ̀ ,

wúrà dídára di àìdán!

Òkúta ibi mímọ́ túká

oríta gbogbo òpópó.

2 Báwo ni àwọn ̀dọ́mọkùnrin Sioni ó ṣe iyebíye,

wọ́n fi wúrà dídára ṣe

dàbí ìkòkò amọ̀ lásán

iṣẹ́ ọwọ́ amọ̀kòkò!

3 Àwọn ajáko pèsè ọmú wọn

fún ìtọ́àwọn ọmọ wọn,

ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi láì lọ́kàn

ògòǹgò aginjù.

4 Nítorí òǹgbẹ, ahọ́n àwọn ọmọ ọwọ́

lẹ̀ mọ́ òkè ẹnu wọn;

àwọn ọmọdé bẹ̀bẹ̀ fún oúnjẹ,

ṣùgbọ́n ẹni ó fi fún wọn.

5 Àwọn ó ń jẹ ohun dáradára

di òtòṣì òpópó.

Àwọn a fi aṣọ dáradára wọ̀

ni wọ́n sùn orí òkìtì eérú.

6 Ìjìyà àwọn ènìyàn mi

tóbi ju ti Sodomu lọ,

a ipò òjijì

láìsí ọwọ́ láti ràn án lọ́wọ́.

7 Ọmọ ọba ọkùnrin wọn mọ́ ju òjò-dídì,

wọ́n funfun ju wàrà lọ

wọ́n ni ìtọ́iyùn pupa,

ìrísí wọn dàbí safire.

8 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n dúdú ju èédú;

wọn wọn mọ̀ òpópó.

Ara wọn hun mọ́ egungun;

ó gbẹ igi gbígbẹ.

9 Àwọn ó nípasẹ̀ idà sàn

ju àwọn ìyàn pa;

ó wọ àkísà ebi, ó ń ṣòfò

fún àìní oúnjẹ láti inú pápá.

10 Pẹ̀ọwọ́ àwọn obìnrin aláàánú

ni wọ́n ṣe ọmọ wọn jẹ

ó di oúnjẹ fún wọn

nígbà a pa àwọn ènìyàn mi run.

11 Olúwa ti fi ihò kíkún fún ìbínú rẹ̀;

ó ìbínú gbígbóná rẹ̀ jáde.

Ó da iná Sioni

ó ìpìlẹ̀ rẹ̀ run.

12 Àwọn ọba ayé gbàgbọ́,

tàbí àwọn ènìyàn ayé,

àwọn ̀àti aninilára le wọ

odi ìlú Jerusalẹmu.

13 Èyí ṣẹlẹ̀ nítorí ̀ṣẹ̀ àwọn wòlíì

àti àìṣedéédéé àwọn olórí àlùfáà,

ó ta ̀jẹ̀ àwọn olódodo

sílẹ̀ láàrín rẹ̀.

14 Nísinsin yìí wọ́n ń rìn kiri òpópó

ọkùnrin ó fọ́.

̀jẹ̀ ara wọn sọ wọ́n di àbàwọ́n

sẹ́ni láyà láti fọwọ́ kan aṣọ wọn.

15 "Lọ kúrò! ̀yin di aláìmọ́!" ni àwọn ènìyàn ń kígbe wọn.

"lọ! lọ! ṣe fọwọ́ kàn !"

Àwọn ènìyàn láàrín orílẹ̀-èdè ,

"Wọn yóò tẹ̀síbí mọ́."

16 Olúwa ti wọn fúnra rẹ̀;

bojútó wọn mọ́.

̀wọ̀ fún olórí àlùfáà mọ́,

àti àánú fún àwọn àgbàgbà.

17 Síwájú i, ojú wa kùnà

fún wíwo ìrànlọ́wọ́ asán;

láti orí ìṣọ́ wa ni à ń

fún orílẹ̀-èdè le gbà .

18 Wọ́n ń ṣọ́ wa kiri,

àwa le rìn òpópó wa mọ́.

Òpin wa ti súnmọ́, ọjọ́ wa níye

nítorí òpin wa ti .

19 Àwọn ń wa yára

ju idì ojú ̀run lọ;

wọ́n wa gbogbo orí òkè

wọ́n gẹ̀gùn aginjù.

20 Ẹni àmì òróró Olúwa, èémí ìyè wa,

ni wọ́n fi tàkúté wọn .

Àwa lábẹ́ òjìji rẹ̀

ni àwa yóò máa gbé láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo.

21 yọ̀ inú yín dùn, ̀yin ọmọbìnrin Edomu,

̀yin ń gbé ilẹ̀ Usi.

Ṣùgbọ́n, a ó gbé ago náà kọjá sọ́dọ̀ rẹ pẹ̀;

ìwọ yóò ̀mùtí, ìwọ yóò rìn ìhòhò.

22 Ìwọ ọmọbìnrin Sioni, ìjìyà rẹ yóò dópin;

ìgbèkùn rẹ pẹ́ mọ́.

Ṣùgbọ́n, ìwọ ọmọbìnrin Edomu, yóò jẹ ̀ṣẹ̀ rẹ

yóò fi àìṣedéédéé rẹ hàn kedere.

Veja também

Publicidade
Lamentações
Ver todos os capítulos de Lamentações
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-