Pular para o conteúdo
Publicidade

Marcos 12

Òwe àwọn ayálégbé

1 12.1-12: Mt 21.33-46; Lk 20.9-19; Isa 5.1-7. Lẹ́yìn ìgbà Jesu pa àwọn olórí ̀sìn lẹ́nu mọ́, ó bẹ̀rẹ̀ í fi òwe wọn sọ̀rọ̀ , "Ọkùnrin kan gbin ọgbà àjàrà kan. Ó ṣe ọgbà yìí , ó ibi ìfúntí wáìnì, ó kọ́ ilé ìṣọ́ i ó fi ṣe àgbàtọ́fún àwọn olùṣọ́gbà, ó lọ ìrìnàjò ó jìnnà. 2 Lákokò ìkórè, ọkùnrin náà rán ̀kan nínú àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ àwọn olùṣọ́gbà náà, ó gbà nínú èso ọgbà àjàrà náà lọ́wọ́ àwọn olùṣọ́gbà. 3 Ṣùgbọ́n àwọn àgbẹ̀ wọ̀n-ọn-nì lu ìránṣẹ́ ọkùnrin náà, wọ́n rán an padà lọ́wọ́ òfo. 4 Ó tún rán ọmọ ̀dọ̀ mìíràn wọn. àwọn àgbẹ̀ ti tún ọmọ ̀dọ̀ ó rán wọn; wọ́n ú. Àní, wọ́n tilẹ̀ ọgbẹ́ i lórí, wọn rán an lọ ni ìtìjú. 5 Ó tún rán òmíràn, èyí n wọ́n pa, àti ̀pọ̀ mìíràn, wọ́n lu òmíràn wọ́n pa òmíràn.

6 "Ìránṣẹ́ kan ṣoṣo Baba olóko ì ì rán níṣẹ́, èyí ni ọmọ òun tìkára rẹ̀. Níkẹyìn ó ran an àwọn olùṣọ́gbà náà, pẹ̀èrò , Wọn yóò bu ọlá fún ọmọ òun.

7 "Ṣùgbọ́n àwọn olùṣọ́gbà wọ̀n-ọn-nì fún ara wọn , Èyí yìí ni àrólé. , jẹ́ a pa á, ogún rẹ̀ yóò jẹ́ tiwa. 8 Báyìí ni wọ́n ọmọ náà wọ́n pa á. Wọ́n wọ́ òkú rẹ̀ jáde kúrò nínú ọgbà àjàrà náà.

9 "ni olúwa ọgbà àjàrà yóò ṣe nígbà ó gbọ́ ohun ó ṣẹlẹ̀. Dájúdájú yóò pa àwọn ẹni ibi wọ̀nyí. Yóò gba àwọn olùtọ́mìíràn sínú oko rẹ̀. 10 12.10-11: Sm 118.22-23; Ap 4.11; 1Pt 2.7.Tàbí ̀yin ì ka ẹsẹ yìí nínú ìwé mímọ́:

" Òkúta àwọn ̀mọ̀kọ̀sílẹ̀

òun náà ni ó di pàtàkì igun ilé.

11 Èyí ni iṣẹ́ Olúwa

ó jẹ́ ìyàlẹ́nu lójú tiwa?"

12 12.12: Mk 11.18. Àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin pẹ̀àwọn àgbàgbà fẹ́ Jesu lákokò náà. Nítorí wọ́n mọ̀ àwọn ń pòwe mọ́ nínú ̀rọ̀ rẹ̀. Àwọn ni alágbàtọ́búburú nínú ìtàn rẹ̀. Ṣùgbọ́n ̀ń wọ́n láti fọwọ́ kàn án nítorí wọ́n bẹ̀ìhùwàsí ̀pọ̀ ènìyàn lọ́dọ̀ rẹ̀. Nítorí náà wọ́n fi í sílẹ̀ lọ.

Sísan owó orí fún Kesari

13 12.13-17: Mt 22.15-22; Lk 20.20-26. 12.13: Mk 3.6; Lk 11.54. Ṣùgbọ́n wọ́n rán àwọn Farisi pẹ̀àwọn kan í ṣe ọmọ-ẹ̀yìn Herodu sọ́dọ̀ Jesu, láti fi ̀rọ̀ a lẹ́nu , títí yóò fi sọ ohun kan wọn fi . 14 wọn ti ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n , "Olùkọ́, àwa mọ̀ ìwọ máa ń sọ òtítọ́ láìsí ìbẹ̀ẹnikẹ́ni. Ṣùgbọ́n òtítọ́ ̀rọ̀ Ọlọ́run ni ìwọ máa ń kọ́ni. Nísinsin yìí, sọ fún wa, ó tọ́ tàbí tọ́ láti máa san owó orí fún Kesari?" 15 àwa ó fi fún un, tàbí a máa fi fún un?

Ṣùgbọ́n Jesu mọ ìwà àgàbàgebè wọn. Ó , "Èéṣe ̀yin fi n fi èyí dán mi wo? owó idẹ kan n ó." 16 Nígbà wọ́n owó idẹ náà fún un, ó bi wọ́n léèrè , "ó! Àwòrán àti orúkọ ta ni ó níbẹ̀?"

Wọ́n dáhùn , "Àwòrán àti orúkọ Kesari ni."

17 12.17: Ro 13.7. Nígbà náà ni Jesu fún wọn , "ó bẹ́̀, fi ohun ó jẹ́ ti Kesari fún Kesari. Ṣùgbọ́n fi ohun gbogbo í ṣe ti Ọlọ́run fún Ọlọ́run."

Ẹnu wọ́n gidigidi èsì rẹ̀.

Ìgbéyàwó àjíǹde

18 12.18-27: Mt 22.23-33; Lk 20.27-38. Àwọn Sadusi tún sọ́dọ̀ rẹ̀, àwọn wọ̀nyí gbàgbọ́ àjíǹde ń bẹ. Ìbéèrè wọn ni , 19 12.19: De 25.5."Olùkọ́, Mose fún wa òfin , nígbà ọkùnrin kan láìbí ọmọ, arákùnrin rẹ̀ gbọdọ̀ ṣú ìyàwó náà lópó wọn bímọ orúkọ ọkọ ó náà. 20 Ǹjẹ́ àwọn arákùnrin méje kan , èyí ó dàgbà jùlọ gbéyàwó, ó àìlọ́mọ. 21 Arákùnrin rẹ̀ kejì ṣú obìnrin ó fi sílẹ̀ lópó, láìpẹ́, òun pẹ̀tún láìbímọ. Arákùnrin kẹta ṣú obìnrin yìí lópó tún bákan náà láìbímọ. 22 Àwọn méjèèje ṣú u lópó, wọn fi ọmọ sílẹ̀. ìkẹyìn gbogbo wọn, obìnrin náà pẹ̀. 23 Ǹjẹ́ àjíǹde, nígbà wọ́n jíǹde, aya ta ni yóò ha ṣe nínú wọn? Àwọn méjèèje ni ó ni aya?"

24 Jesu dáhùn ó fún wọn , "í ṣe nítorí èyí ni ṣe ṣìnà, ̀yin mọ ìwé Mímọ́, tàbí agbára Ọlọ́run. 25 Nítorí , nígbà àwọn arákùnrin méje yìí àti obìnrin náà dìde nínú òkú, a ṣe ìgbéyàwó fún wọn. Wọn yóò dàbí àwọn angẹli ń bẹ ̀run. 26 12.26: Ek 3.6.Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, nípa bóyá àjíǹde yóò . Àbí ̀yin ì ka ìwé Eksodu, nípa Mose àti pápá ń ? Ọlọ́run sọ fún Mose , Èmi ni Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu. 27 Òun í ṣe Ọlọ́run àwọn òkú ṣe Ọlọ́run àwọn alààyè: nítorí ̀yin ṣe àṣìṣe gidigidi."

Òfin ó ga jùlọ

28 12.28-34: Mt 22.34-40; Lk 20.39-40; 10.25-28. ̀kan nínú àwọn olùkọ́ òfin ti ó dúró níbẹ̀ ó fetísílẹ̀ dáradára àròyé yìí ṣàkíyèsí , Jesu ti dáhùn dáradára. Òun pẹ̀béèrè lọ́wọ́ Jesu , "Nínú gbogbo òfin, èwo ṣe pàtàkì jùlọ?"

29 12.29: De 6.4. Jesu ọkùnrin yìí lóhùn , "Èyí ṣe pàtàkì jùlọ nínú àwọn òfin ni èyí ó báyìí , Gbọ́ Israẹli; Olúwa Ọlọ́run wa Olúwa kan ni. 30 ìwọ ó fi gbogbo àyà rẹ, àti gbogbo ọkàn rẹ, àti gbogbo ̀rẹ, àti gbogbo agbára rẹ fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ, èyí òfin kìn-ín-ní. 31 12.31: Le 19.18; Ro 13.9; Ga 5.14; Jk 2.8.Èkejì ni : Fẹ́ ọmọnìkejì rẹ.òfin mìíràn ga ju méjèèjì yìí lọ."

32 Olùkọ́ òfin náà dáhùn , "Olùkọ́, ìwọ sọ òtítọ́ nípa Ọlọ́run kan ni ó ń bẹ, àti òmíràn àfi òun nìkan. 33 12.33: 1Sa 15.22; Ho 6.6; Mt 6.6-8; Mt 9.13.Àti a fi gbogbo àyà, àti gbogbo òye, àti gbogbo ọkàn àti gbogbo agbára fẹ́ , àti fẹ́ ọmọnìkejì ẹni ara ẹni, ó ju gbogbo ẹbọ sísun, àti ẹbọ lọ."

34 Jesu i dájú òye ọkùnrin yìí ga, nítorí náà, Jesu sọ fún un , "Arákùnrin, ìwọ jìnà à ti ìjọba ̀run." Láti ìgbà náà lọ, ẹnikẹ́ni tún béèrè ohun kan lọ́wọ́ Jesu.

Ọmọ ta ni Kristi ń ṣe?

35 12.35-37: Mt 22.41-46; Lk 20.41-44. Lẹ́yìn náà, nígbà Jesu ń kọ́ àwọn ènìyàn nínú tẹmpili, ó béèrè lọ́wọ́ wọn , "Èéṣe àwọn olùkọ́ òfin fi gbà Kristi náà láti jẹ́ ọmọ Dafidi? 36 12.36: Sm 110.1; Ap 2.34-35; Hb 1.13.Nítorí Dafidi tìkára rẹ̀, ti ń ti ipa ̀Mímọ́ sọ̀rọ̀ :

" Olúwa sọ fún Olúwa mi :

"Jókòó ọwọ́ ̀tún mi,

títí èmi yóò fi sọ àwọn ̀rẹ

di àpótí ìtìsẹ̀ rẹ." 

37 Níwọ́n ìgbà Dafidi tìkára rẹ̀ é Olúwa,báwo ni ó túnṣe jẹ́ ọmọ rẹ̀?"

̀pọ̀ ènìyàn fi ayọ̀ gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀.

38 12.38-40: Mt 23.5-7; Lk 20.46-47; Lk 11.43. Ó fún wọn nínú ̀kọ́ rẹ̀ , "ṣọ́ra fun àwọn olùkọ́ òfin wọ́n fẹ́ láti máa wọ aṣọ gígùn káàkiri, wọ́n fẹ́ ìkíni ọjà, 39 àti ibùjókòó ọlá nínú Sinagọgu àti ipò ọlá níbi àsè. 40 Àwọn wọ́n jẹ ilé àwọn opó rún, wọ́n ń gbàdúrà gígùn fún àṣehàn, nítorí èyí, ìjìyà wọn yóò pọ̀ púpọ̀."

̀rẹ́ opó

41 12.41-44: Lk 21.1-4; Jh 8.20. Jesu jókòó òdìkejì kọjú àpótí ìṣúra: ó ń wo ìjọ ènìyàn ti ń sọ owó sínú àpótí ìṣúra, ̀pọ̀ àwọn ọlọ́rọ̀ sọ púpọ̀ i. 42 Ṣùgbọ́n obìnrin opó kan , ó fi ààbọ̀ owó idẹ méjì síbẹ̀, ì ṣe ìdá méjì owó-babà kan sínú rẹ̀.

43 Jesu pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó sọ fún wọn , "Lóòótọ́ ni mo fún yin , tálákà opó yìí sọ sínú àpótí ìṣúra ju gbogbo àwọn ìyókù to sọ sínú rẹ lọ. 44 Nítorí , àwọn ìyókù nínú ̀pọ̀ ìní wọ́n, ṣùgbọ́n tirẹ̀, nínú àìní rẹ̀, ó sọ gbogbo ohun ó náà sílẹ̀ àní gbogbo ìní rẹ̀."

Veja também