Publicidade

Marcos 4

Òwe afúnrúgbìn

1 Jesu tún bẹ̀rẹ̀ ń kọ́ni létí Òkun, àwọn ìjọ ènìyàn ó i pọ̀ jọjọ bẹ́̀ ó fi bọ́ sínú ọkọ̀ ojú omi, ó jókòó nínú rẹ̀ lẹ́gbẹ̀́ Òkun, nígbà àwọn ènìyàn ilẹ̀ létí Òkun. 2 Ó bẹ̀rẹ̀ í fi òwe wọn sọ̀rọ̀ nínú ̀kọ́ rẹ̀ , 3 "fi etí sílẹ̀! ọjọ́ kan, afúnrúgbìn kan jáde lọ láti lọ fúnrúgbìn rẹ̀. 4 ó ti ń fúnrúgbìn, díẹ̀ bọ́ ̀̀, àwọn ẹyẹ , wọ́n ṣà á jẹ. 5 Díẹ̀ bọ́ sórí ilẹ̀ àpáta, níbi erùpẹ̀ ko púpọ̀. Láìpẹ́ ọjọ́, ó hu jáde. 6 Ṣùgbọ́n nígbà oòrùn gangan, ó jóná, nítorí gbòǹgbò, ó gbẹ. 7 Àwọn irúgbìn mìíràn bọ́ sáàrín ̀gún, nígbà ̀gún dàgbàsókè, ó fún wọn pa, bẹ́̀ àwọn irúgbìn náà le so èso. 8 Ṣùgbọ́n òmíràn bọ́ ilẹ̀ ọlọ́ràá, o so èso lọ́pọ̀lọ́pọ̀, òmíràn ọgbọọgbọ̀n, òmíràn ọgọọgọ́ta, àti òmíràn ọgọọgọ́rùn-ún."

9 Jesu , "Ẹni ó etí láti fi gbọ́, ó gbọ́."

10 Nígbà ó ku òun nìkan pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn méjìlá àti àwọn mìíràn, wọ́n bi í léèrè , "ni ìtumọ̀ òwe rẹ̀?" 11 Ó wọn lóhùn , "̀yin ni a gbà láààyè láti mọ ohun ìjìnlẹ̀ nípa ìjọba Ọlọ́run. Èyí ó pamọ́ àwọn ó lẹ́yìn agbo ìjọba náà. 12 ó tilẹ̀ jẹ́ ,

" wọn yóò i, wọn yóò gbọ́, yóò wọn,

bẹ́̀ ni wọn yóò yípadà Ọlọ́run.

Tàbí a dárí ̀ṣẹ̀ wọ́n!’ "

13 Ṣùgbọ́n Jesu fún wọn , "òwe ó rọrùn yìí e yín? Báwo ni ̀yin yóò ṣe mọ ìtumọ̀ àwọn mìíràn mo ń sọ fún un yín? 14 Afúnrúgbìn ń fúnrúgbìn ̀rọ̀ náà. 15 Àwọn èso bọ́ ojú ̀, ni àwọn ọlọ́kàn líle wọ́n gbọ́ ̀rọ̀ Ọlọ́run, lójúkan náà èṣù ó wọn gbàgbé ohun wọ́n ti gbọ́. 16 Bákan náà, àwọn ó bọ́ sórí àpáta, ni àwọn ènìyàn wọ́n fi ayọ̀ gbọ́ ̀rọ̀ Ọlọ́run. 17 Ṣùgbọ́n ni gbòǹgbò ó jinlẹ̀ ọkàn wọn. Ṣùgbọ́n wọ́n á fún ìgbà díẹ̀, lẹ́yìn náà nígbà ti wàhálà tàbí inúnibíni dìde nítorí ̀rọ̀ náà, lójúkan náà, wọ́n á kọsẹ̀. 18 Àwọn ó bọ́ sáàrín ̀gún ni àwọn ó gbọ́ ̀rọ̀ náà, wọn gbà á. 19 Ṣùgbọ́n láìpẹ́ jọjọ, àwọn adùn ayé àti inú dídùn, ọrọ̀ àti ìjàkadì fún àṣeyọrí àti ìfẹ́ àwọn ohun mèremère ayé, gba ọkàn wọn, wọ́n fún ̀rọ̀ náà pa ọkàn wọn. ̀rọ̀ náà jẹ́ aláìléso. 20 Ṣùgbọ́n àwọn ó bọ́ ilẹ̀ ọlọ́ràá, àwọn ó gbọ́ ̀rọ̀ Ọlọ́run wọ́n gbà á lóòtítọ́, wọ́n èso púpọ̀ jáde fún Ọlọ́run ọgbọọgbọ̀n, ọgọọgọ́ta, àti òmíràn ọgọọgọ́rùn-ún, gẹ́gẹ́ a ti gbìn ín ọkàn wọn."

Àtùpà lórí ̀fìtílà

21 Ó fún wọn , "A ha gbé fìtílà láti fi sábẹ́ òsùwọ̀n tàbí sábẹ́ àkéte? Rárá o, ki a ṣe pe a o gbé e ka orí ̀fìtílà? 22 Gbogbo ohun ó pamọ́ nísinsin yìí yóò hàn gbangba ọjọ́ kan, bẹ́̀ ni ohun ó ìkọ̀kọ̀, ṣe ó le yọ gbangba. 23 ẹnikẹ́ni etí láti fi gbọ́, ó gbọ́."

24 Ó tún tẹ̀síwájú , "máa kíyèsi ohun gbọ́ dáradára, nítorí òsùwọ̀n ̀yin fi wọ́n náà ni a ó fi wọ́n fún un yín àti bẹ́̀ lọ. 25 Nítorí ẹni ó , òun ni a ó tún fi fún i àti lọ́wọ́ ẹni , ni a ó ti gba èyí náà ó ."

Òwe irúgbìn ń dàgbà

26 Ó tún sọ èyí , "Èyí ni a fi ìjọba Ọlọ́run . Ọkùnrin kan ń fúnrúgbìn ilẹ̀. 27 Lóru àti ̀sán, bóyá ó sùn tàbí ó dìde, irúgbìn náà hu jáde, ó dàgbà, òun mọ̀ ó ti ṣẹlẹ̀. 28 Nítorí ilẹ̀ kọ́kọ́ èso jáde fún ara rẹ̀, ó èéhù ewé jáde, èyí ó tẹ̀e orí ọkà, ìparí, ọkà náà gbó. 29 Nígbà èso gbó tán, lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀, òun a tẹ dòjé bọ inú ọkà náà, ó kórè rẹ̀."

Òwe musitadi

30 Jesu tún , "ni èmi fi ìjọba Ọlọ́run ? Òwe wo ni èmi fi ṣe àkàwé rẹ̀? 31 Ó dàbí èso hóró musitadi kan, lóòótọ́, ó jọ ̀kan nínú àwọn èso ó kéré jùlọ ti a gbìn sínú ilẹ̀. 32 Síbẹ̀, nígbà a gbìn ín, ó dàgbàsókè, ó gbilẹ̀, ó di títóbi ju gbogbo ewéko inú ọgbà yòókù lọ. Ó yọ ̀ka ńlá níbi àwọn ẹyẹ ̀run kọ́ ìtẹ́ wọn , wọn ìdáàbòbò."

33 Òun lo ̀pọ̀ irú òwe wọ̀nyí láti fi kọ́ àwọn ènìyàn, gẹ́gẹ́ wọ́n ti ń fẹ́ láti òye . 34 Kìkì òwe ni Jesu fi ń kọ́ àwọn ènìyàn ̀kọ́ ìta gbangba rẹ̀. Ṣùgbọ́n lẹ́yìn èyí, nígbà ó pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, òun a sọ ìtumọ̀ ohun gbogbo.

Jesu afẹ́fẹ́ okun dákẹ́ jẹ́́

35 Nígbà alẹ́ lẹ́, Jesu fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "jẹ́ a rékọjá apá kejì." 36 Nígbà wọn ti ìjọ , wọ́n gbà á sínú ọkọ̀ ojú omi gẹ́gẹ́ ó ti . Àwọn ọkọ̀ ojú omi kékeré mìíràn lọ́dọ̀ rẹ̀. 37 Ìjì líle ńlá kan dìde, omi ń sínú ọkọ̀, bẹ́̀ ọkọ̀ fi bẹ̀rẹ̀ í kún fún omi, ó fẹ́rẹ . 38 Jesu ti sùn lọ lẹ́yìn ọkọ̀, ó gbé orí ìrọ̀. Wọ́n i lóhùn rara , "Olùkọ́ni, tàbí ìwọ tilẹ̀ bìkítà gbogbo wa fẹ́ ?"

39 Ó dìde, ó ìjì líle náà , ó fún òkun , "Dákẹ́! Jẹ́́!" Ìjì náà , ìparọ́rọ́ ńlá .

40 Lẹ́yìn náà, ó béèrè lọ́wọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Èéṣe ̀yin fi ń ṣojo bẹ́̀? Tàbí ̀yin ì ì ìgbàgbọ́ síbẹ̀síbẹ̀?"

41 ̀wọ́n gidigidi, wọ́n fún ara wọn , "Irú ọkùnrin wo ni èyí, ìjì àti Òkun ń gbọ́ tirẹ̀!"

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-