Pular para o conteúdo
Publicidade

Mateus 14

A bẹ́ Johanu Onítẹ̀bọmi lórí

1 14.1-2: Mk 6.14-16; Lk 9.7-9; Mk 8.28. àkókò náà ni Herodu ọba tetrarki gbọ́ nípa òkìkí Jesu, 2 ó fún àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ , "Dájúdájú Johanu onítẹ̀bọmi ni èyí, ó jíǹde kúrò nínú òkú. Ìdí nìyí ó fi agbára láti ṣiṣẹ́ ìyanu wọ̀nyí."

3 14.3-4: Mk 6.17-18; Lk 3.19-20; Le 18.16; 20.21. Nísinsin yìí Herodu ti Johanu, ó fi ̀wọ̀n é, ó fi sínú túbú, nítorí Herodia aya Filipi arákùnrin rẹ̀, 4 nítorí Johanu onítẹ̀bọmi ti sọ fún Herodu , "yẹ fún láti fẹ́ obìnrin náà." 5 14.5-12: Mk 6.19-29.Herodu fẹ́ pa Johanu, ṣùgbọ́n ó bẹ̀àwọn ènìyàn nítorí gbogbo ènìyàn gbàgbọ́ wòlíì ni.

6 ọjọ́ àsè ìrántí ọjọ́ ìbí Herodu, ọmọ Herodia obìnrin dáradára, ó tẹ́ Herodu lọ́run gidigidi. 7 Nítorí náà ni ó ṣe fi ìbúra ṣe ìlérí láti fún un ohunkóhun ti ó béèrè fún. 8 Pẹ̀ìmọ̀ràn láti ̀dọ̀ ìyá rẹ̀, ó béèrè , "Fún mi ni orí Johanu onítẹ̀bọmi nínú àwopọ̀kọ́". 9 Inú ọba bàjẹ́ gidigidi, ṣùgbọ́n nítorí ìbúra rẹ̀ àti ojú ba à í níwájú àwọn àlejò ba jẹ àsè, ó pàṣẹ wọ́n fún un gẹ́gẹ́ o ti fẹ́. 10 Nítorí náà, a bẹ́ orí Johanu onítẹ̀bọmi nínú ilé túbú. 11 A gbé orí rẹ̀ jáde láti fi fún ọmọbìnrin náà nínú àwopọ̀kọ́, òun gbà á, ó gbé e tọ ìyá rẹ̀ lọ. 12 Lẹ́yìn náà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu gba òkú rẹ̀, wọ́n sin ín. Wọ́n sọ ohun ó ṣẹlẹ̀ fún Jesu.

Jesu bọ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn

13 14.13-21: Mk 6.32-44; Lk 9.10-17; Jh 6.1-13; Mt 15.32-38. Nígbà Jesu gbọ́ ìròyìn ìṣẹ̀lẹ̀ náà, ó kúrò níbẹ̀, ó ọkọ̀ ojú omi lọ ibi kọ́lọ́fín kan èbúté láti níbẹ̀. Nígbà wọ́n gbọ́ èyí, ̀pọ̀ ènìyàn fi ẹsẹ̀ rìn tẹ̀e láti ̀pọ̀ ìlú wọn. 14 Nígbà ti Jesu gúnlẹ̀, ó ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, inú rẹ̀ yọ́ wọn, ó àwọn aláìsàn láradá.

15 Nígbà ti ilẹ̀ ń ṣú lọ, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ́ , wọ́n , "Ibi yìí jìnnà ìlú ilẹ̀ ń ṣú lọ. Rán àwọn ènìyàn lọ àwọn ìletò wọ́n ra oúnjẹ jẹ."

16 Ṣùgbọ́n Jesu fèsì , "nílò wọ́n lọ kúrò. fún wọn oúnjẹ."

17 Wọ́n dalóhùn , "Àwa ju ìṣù àkàrà márùn-ún àti ẹja méjì lọ níhìn-ín."

18 Ó , "wọn fún mi níhìn-ín yìí." 19 14.19: Mk 14.22; Lk 24.30.Lẹ́yìn náà, ó fún àwọn ènìyàn wọ́n jókòó lórí koríko. Lẹ́yìn náà, ó ìṣù àkàrà márùn-ún àti ẹja méjì. Ó gbé ojú rẹ̀ ̀run. Ó béèrè ìbùkún Ọlọ́run lórí oúnjẹ náà, Ó ú, ó fi àkàrà náà fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn láti pín in fún àwọn ènìyàn. 20 Gbogbo wọn jẹ àjẹyó. Lẹ́yìn náà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn àjẹkù jọ, ó kún agbọ̀n méjìlá. 21 Iye àwọn ènìyàn ni ọjọ́ náà jẹ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ọkùnrin, láìka àwọn obìnrin àti àwọn ọmọdé.

Jesu rìn lójú omi

22 14.22-23: Mk 6.45-46; Jh 6.15-17. Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ lẹ́yìn èyí, Jesu fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wọ́n bọ sínú ọkọ̀ wọn, àti wọ́n máa kọjá lọ ṣáájú rẹ̀ òdìkejì. Òun náà dúró lẹ́yìn láti àwọn ènìyàn lọ ilé wọn. 23 Lẹ́yìn ó ìjọ ènìyàn tán, ó gun orí òkè lọ fúnra rẹ̀ láti lọ gba àdúrà. Nígbà ilẹ̀ ṣú, òun nìkan níbẹ̀, 24 14.24-33: Mk 6.47-52; Jh 6.16-21.àkókò yìí ọkọ̀ ojú omi náà ti rin jìnnà etí bèbè Òkun, ìjì omi ń í síwá sẹ́yìn, nítorí ìjì ṣe ọwọ́ òdì wọn.

25 déédé ago mẹ́rin òwúrọ̀, Jesu tọ̀ wọ́n , ó ń rìn lórí omi. 26 14.26: Lk 24.37.Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn i ó ń rìn lójú omi, ̀ba wọn gidigidi, wọ́n "iwin ni," wọ́n kígbe tìbẹ̀tìbẹ̀.

27 Lójúkan náà, Jesu fún wọn , "ọkàn le! Èmi ni ṣe bẹ̀."

28 Peteru i , "Olúwa, ó jẹ́ ìwọ ni nítòótọ́, sọ n tọ̀ ́ lórí omi."

29 14.29: Jh 21.7. Jesu a lóhùn , "Ó dára, máa bọ̀ ."

Nígbà náà ni Peteru sọ̀kalẹ̀ láti inú ọkọ̀. Ó ń rìn lórí omi lọ ìhà ̀dọ̀ Jesu. 30 Nígbà ó afẹ́fẹ́ líle, ̀á, ó bẹ̀rẹ̀ í . Ó kígbe lóhùn rara , "Gbà , Olúwa."

31 14.31: Mt 6.30; 8.26; 16.8. Lójúkan náà, Jesu na ọwọ́ rẹ̀, ó dìímú, ó gbà á. Ó fún un , "Èéṣe ìwọ fi ṣiyèméjì ìwọ onígbàgbọ́ kékeré?"

32 Àti , nígbà ti wọ́n gòkè sínú ọkọ̀, ìjì náà dúró jẹ́́. 33 14.33: Mt 28.9,17.Nígbà náà ni àwọn to nínú ọkọ̀ náà foríbalẹ̀ fún un wọ́n , "Nítòótọ́ Ọmọ Ọlọ́run ni ìwọ í ṣe."

34 14.34-36: Mk 6.53-56; Gẹ 6.22. Nígbà wọn rékọjá apá kejì wọ́n gúnlẹ̀ Genesareti. 35 Nígbà tiwọn mọ̀ Jesu ni, wọn ránṣẹ́ gbogbo ìlú náà yíká. Wọ́n gbé gbogbo àwọn aláìsàn tọ̀ ́ . 36 14.36: Mk 3.10; Nu 15.38; Mt 9.20.Àwọn aláìsàn bẹ̀ ́ ó gba àwọn láyè láti fi ọwọ́ kan ìṣẹ́aṣọ rẹ̀, gbogbo àwọn ó ṣe bẹ́̀ ìwòsàn.

Veja também