15 "Ṣùgbọ́n ẹyin ń kọ?" Ó bi í léèrè pé, "Ta ni ẹ̀yin ń fi mi pè?"
16 16.16: Mt 1.16; Jh 11.27; 1.49. Simoni Peteru dáhùn pé, "Ìwọ ni Kristi náà, Ọmọ Ọlọ́run alààyè."
17 16.17: 1Kọ 15.50; Ga 1.16; Ef 6.12; Hb 2.14. Jesu sì wí fún un pé, "Alábùkún fún ni ìwọ Simoni ọmọ Jona, nítorí ẹran-ara àti ẹ̀jẹ̀ kọ́ ló fi èyí hàn bí kò ṣe Baba mi tí ó ń bẹ ní ọ̀run.