Publicidade

Romanos 5

Àlàáfíà àti ayọ̀

1 Nítorí náà, níwọ̀n ìgbà a ti wa láre nípa ìgbàgbọ́, àwa àlàáfíà lọ́dọ̀ Ọlọ́run nípasẹ̀ Olúwa wa Jesu Kristi. 2 Nípasẹ̀ ẹni àwa ti ̀gbà nípa ìgbàgbọ́ inú oore-ọ̀fẹ́ yìí nínú èyí àwa gbé dúró. Àwa ń yọ̀ nínú ìrètí ògo Ọlọ́run. 3 í ṣe bẹ́̀ nìkan, ṣùgbọ́n àwa tún ń ṣògo nínú ìjìyà pẹ̀, a ti mọ̀ ìjìyà ń ṣiṣẹ́ sùúrù; 4 àti sùúrù ń ṣiṣẹ́ ìwà rere; àti ìwà rere ń ṣiṣẹ́ ìrètí. 5 Ìrètí í í dójúti ni nítorí a ti ìfẹ́ Ọlọ́run wa lọ́kàn láti ọwọ́ ̀Mímọ́ a fi fún wa.

6 Nítorí ìgbà àwa jẹ́ aláìlera, àkókò ó yẹ, Kristi fún àwa aláìwà-bí-Ọlọ́run. 7 Nítorí ó ṣọ̀wọ́n ẹnìkan fún olódodo, ṣùgbọ́n fún ènìyàn rere bóyá ẹlòmíràn tilẹ̀ dábàá láti . 8 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run fi ìfẹ́ òun pàápàá wa hàn nínú èyí , nígbà àwa jẹ́ ẹlẹ́ṣẹ̀, Kristi fún wa.

9 Mélòó mélòó ni a wa láre nísinsin yìí nípa ̀jẹ̀ rẹ̀ ni a ó gbà kúrò nínú ìbínú nípasẹ̀ rẹ̀. 10 Ǹjẹ́, nígbà àwa ̀, a wa, ba Ọlọ́run làjà nípa ikú Ọmọ rẹ̀, mélòó mélòó, nígbà a ìjà tan, ni a ó gbà nípa ìyè rẹ̀. 11 í ṣe bẹ́̀ nìkan, ṣùgbọ́n àwa ń ṣògo nínú Ọlọ́run nípa Olúwa wa Jesu Kristi, nípasẹ̀ ẹni àwa ti ìlàjà gbà nísinsin yìí.

Ikú nípasẹ̀ Adamu, iyè nípasẹ̀ Jesu

12 Nítorí gẹ́gẹ́ ̀ṣẹ̀ ti tipa ̀dọ̀ ènìyàn kan wọ ayé, àti ikú nípa ̀ṣẹ̀ bẹ́̀ ni ikú kọjá sórí ènìyàn gbogbo, láti ̀dọ̀ ẹni gbogbo ènìyàn ti dẹ́ṣẹ̀.

13 Nítorí òfin , ̀ṣẹ̀ ti láyé; ṣùgbọ́n a ka ̀ṣẹ̀ ni lọ́rùn nígbà òfin . 14 Ṣùgbọ́n ikú jẹ ọba láti ìgbà Adamu títí fi di ìgbà ti Mose, àti lórí àwọn ̀ṣẹ̀ wọn dàbí irú ìrékọjá Adamu, ẹni í ṣe àpẹẹrẹ ẹni ń bọ̀.

15 Ṣùgbọ́n ̀bùn ̀fẹ́ dàbí ̀ṣẹ̀. Nítorí nípa ̀ṣẹ̀. Nítorí o jẹ ẹnìkan ẹni púpọ̀ , mélòó mélòó ni oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run, àti ̀bùn nínú oore-ọ̀fẹ́ ọkùnrin kan, Jesu Kristi, di púpọ̀ fún ẹni púpọ̀. 16 í ṣe nípa ẹnìkan ó sẹ̀ ni ̀bùn náà, nítorí ìdájọ́ ti ipasẹ̀ ẹnìkan fún ìdálẹ́bi, ṣùgbọ́n ̀bùn ̀fẹ́ ti inú ̀ṣẹ̀ púpọ̀ fún ìdáláre. 17 Ǹjẹ́ o jẹ nípa ̀ṣẹ̀ ọkùnrin kan, ikú jẹ ọba nípasẹ̀ ẹnìkan náà; mélòó mélòó ni àwọn ń gba ̀pọ̀lọpọ̀ oore-ọ̀fẹ́ àti ̀bùn òdodo yóò jẹ ọba nínú ìyè nípasẹ̀ ẹnìkan, Jesu Kristi.

18 Ǹjẹ́ o jẹ nípa ̀ṣẹ̀ ẹnìkan ìdájọ́ gbogbo ènìyàn ìdálẹ́bi; gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni nípa ìwà òdodo ẹnìkan, ̀bùn ̀fẹ́ sórí gbogbo ènìyàn fún ìdáláre ìyè. 19 Nítorí gẹ́gẹ́ nípa àìgbọ́ràn ọkùnrin kan, ènìyàn púpọ̀ di ẹlẹ́ṣẹ̀, bẹ́̀ ni nípa ìgbọ́ràn ẹnìkan, a ó sọ ènìyàn púpọ̀ di olódodo.

20 Ṣùgbọ́n òfin bọ́ inú rẹ̀, ̀ṣẹ̀ di púpọ̀, ṣùgbọ́n ni ibi ti ̀ṣẹ̀ di púpọ̀, oore-ọ̀fẹ́ di púpọ̀ rékọjá. 21 , gẹ́gẹ́ ̀ṣẹ̀ ti jẹ ọba nípa ikú bẹ́̀ ni oore-ọ̀fẹ́ jẹ ọba nípa òdodo títí ìyè àìnípẹ̀kun nípasẹ̀ Jesu Kristi Olúwa wa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-