Publicidade

Rute 1

Naomi àti Rutu

1 ìgbà àwọn onídàájọ́ ń ṣe àkóso ilẹ̀ Israẹli, ìyàn kan ilẹ̀ náà, ọkùnrin kan láti Bẹtilẹhẹmu ti Juda, òun àti aya rẹ̀ pẹ̀àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin méjì lọ láti máa gbé ilẹ̀ Moabu fún ìgbà díẹ̀. 2 Orúkọ ọkùnrin náà ń jẹ́ Elimeleki, orúkọ ìyàwó rẹ̀ ni Naomi, orúkọ àwọn ọmọ rẹ̀ méjèèjì ni Maloni àti Kilioni àwọn ará Efrata, ti Bẹtilẹhẹmu ti Juda. Wọ́n lọ ilẹ̀ Moabu, wọ́n ń gbé níbẹ̀.

3 àsìkò wọ́n ń gbé ibẹ̀, Elimeleki, ọkọ Naomi , ó ku òun pẹ̀àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin méjèèjì. 4 Wọ́n fẹ́ àwọn ọmọbìnrin ará Moabu méjì, orúkọ ̀kan ń jẹ́ Oripa, èkejì ń jẹ́ Rutu. Lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti gbé níbẹ̀ fún ọdún mẹ́wàá, 5 Maloni àti Kilioni náà , Naomi láìsí ọkọ tàbí ọmọ kankan fún un mọ́.

Naomi padà láti ilẹ̀ Moabu

6 Nígbà Naomi gbọ́ Moabu ó Olúwa ti bẹ àwọn ènìyàn rẹ̀ nípa fífún wọn ̀pọ̀ oúnjẹ. Ó dìde pẹ̀àwọn ìyàwó ọmọ rẹ̀ méjèèjì láti padà ìlú rẹ̀. 7 Òun pẹ̀àwọn ìyàwó ọmọ rẹ̀ méjèèjì ni wọ́n jọ fi ibi ó ń gbé sílẹ̀ wọ́n bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò wọn padà ilẹ̀ Juda.

8 Ṣùgbọ́n ojú ̀, Naomi fún àwọn aya ọmọ rẹ̀ méjèèjì , "ẹnìkọ̀̀kan yín padà ilé ìyá rẹ̀. Olúwa ṣe àánú fún yín ti ṣe èmi àti àwọn ọkọ yín ó . 9 Olúwa ó fi yín lọ́kàn balẹ̀ ilé ọkọ mìíràn."

Naomi fi ẹnu wọ́n ẹnu "Ó dìgbà," wọ́n sọkún kíkankíkan. 10 Wọ́n fún un , "Rárá, a ó lọ ̀dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ."

11 Ṣùgbọ́n Naomi dáhùn , "padà sílé ̀yin ọmọ mi. Nítorí ni fi fẹ́ pẹ̀mi? Ṣé mo tún le àwọn ọmọkùnrin mìíràn ni, ó le ṣe ọkọ yin? 12 padà sílé, ̀yin ọmọ mi, nítorí èmi ti di arúgbó láti ọkọ mìíràn. èmí , èmí ìrètí, èmí tilẹ̀ ọkọ mìíràn alẹ́ yìí, èmí àwọn ọmọkùnrin mìíràn, 13 ̀yin ha le è dúró dìgbà wọ́n yóò fi dàgbà? ̀yin ó le è dúró wọ́n láì fẹ́ ọkọ mìíràn? Rárá, ̀yin ọmọbìnrin mi, nítorí inú mi bàjẹ́ gidigidi ju tiyín lọ, nítorí ọwọ́ Olúwa fi jáde mi!"

14 Wọ́n gbé ohùn wọn sókè, wọ́n tún sọkún. Nígbà náà Oripa fi ẹnu ko ìyá ọkọ rẹ̀ ẹnu ó dìgbà, ṣùgbọ́n Rutu mọ́ ọn síbẹ̀.

15 Naomi , "ó, arábìnrin rẹ ti padà lọ ̀dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀ àti òrìṣà rẹ̀, ìwọ náà padà pẹ̀rẹ̀."

16 Ṣùgbọ́n Rutu dáhùn , "ṣe rọ̀ láti fi ́ sílẹ̀ tàbí láti padà lẹ́yìn rẹ. Ibi ìwọ lọ èmi yóò lọ, ibi ti ìwọ dúró ni èmi yóò dúró, àwọn ènìyàn rẹ ni yóò jẹ́ ènìyàn mi, Ọlọ́run rẹ ni yóò jẹ́ Ọlọ́run mi. 17 Níbi ìwọ ni èmi yóò , níbẹ̀ ni wọn yóò sin . Olúwa jẹ ìyà ó lágbára, ohunkóhun ṣe ikú ." 18 Nígbà Naomi i Rutu ti pinnu láti tẹ̀òun rọ̀ láti padà mọ́.

19 Àwọn méjèèjì ń lọ títí wọ́n fi ìlú Bẹtilẹhẹmu. Nígbà wọ́n ibẹ̀, ariwo ìpadàbọ̀ wọn gba ìlú kan, àwọn obìnrin ibẹ̀ kígbe ohùn rara , "Naomi ni èyí ?"

20 Naomi dáhùn , "ṣe Naomi mọ́, Mara,1.20 tí ó túmọ̀ sí, Ìkorò nítorí Olódùmarè ti ayé mi di kíkorò. 21 Mo jáde kíkún, ṣùgbọ́n Olúwa mi padà òfo. Nítorí náà kín fi ń Naomi, nígbà Olódùmarè ti kọ̀ sílẹ̀, ó ìdààmú mi?"

22 Báyìí ni Naomi ṣe padà láti Moabu pẹ̀Rutu, ará Moabu ìyàwó ọmọ rẹ̀. Wọ́n gúnlẹ̀ Bẹtilẹhẹmu ìbẹ̀rẹ̀ ìkórè ọkà barle.

Veja também

Rute
Ver todos os capítulos de Rute
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-