Publicidade

Tiago 3

Kíkó ahọ́n ìjánu

1 ̀yin ará mi, ṣe jẹ́ púpọ̀ nínú yín jẹ́ olùkọ́, ̀yin ó mọ̀ àwa ni yóò jẹ̀bi . 2 Nítorí nínú ohun púpọ̀ ni gbogbo wa ń ṣe àṣìṣe. ẹnìkan ṣì ṣe nínú ̀rọ̀, òun náà ni ẹni pípé, òun ni ó le gbogbo ara ìjánu.

3 a fi ìjánu bọ ẹṣin lẹ́nu, wọn ó le gbọ́ tiwa, gbogbo ara wọn ni àwa ń kiri pẹ̀. 4 Kíyèsi i, àwọn ọkọ̀ ojú omi pẹ̀, wọ́n ti tóbi , a ń ti ọwọ́ ̀fúùfù líle gbá kiri, ìtọ́kọ̀ kékeré ni a fi ń darí wọn kiri, síbikíbi ó wu ẹni ó ń tọ́ ọkọ̀. 5 Bẹ́̀ pẹ̀ni ahọ́n jẹ́ ̀kékeré, ó ń fọhùn ohùn ńlá. Wo igi ńlá iná kékeré ń sun jóná! 6 Iná ni ahọ́n, ayé ̀ṣẹ̀ ni: àárín àwọn ̀ara wa, ahọ́n ti ń gbogbo ara jẹ́, yóò ti iná bọ ipa ayé wa; ̀run àpáàdì a tiná bọ òun náà.

7 Nítorí olúkúlùkù ̀ẹranko, àti ti ẹyẹ, àti ti ejò, àti ti ohun ó ń bẹ Òkun, ni à ń lójú, a ti lójú láti ọwọ́ ̀ènìyàn . 8 Ṣùgbọ́n ahọ́n ni ẹnikẹ́ni le lójú; ohun búburú aláìgbọ́ràn ni, ó kún fún oró ikú í pa ni.

9 Òun ni àwa fi ń yin Olúwa àti Baba, òun ni a fi ń ènìyàn a àwòrán Ọlọ́run. 10 Láti ẹnu kan náà ni ìyìn àti èébú ti ń jáde. ̀yin ará mi, nǹkan wọ̀nyí yẹ ó bẹ́̀. 11 Orísun odò kan a ha máa sun omi dídára àti omi iyọ̀ jáde láti orísun kan náà ? 12 ̀yin ará mi, igi ̀pọ̀tọ́ ha le so èso olifi ? Tàbí àjàrà ha so èso ̀pọ̀tọ́? Bẹ́̀ ni orísun kan le sun omíró àti omi tútù.

Oríṣìí ọgbọ́n méjì

13 Ta ni ó gbọ́n ó ìmọ̀ nínú yín? jẹ́ ó fi iṣẹ́ rẹ̀ hàn nípa ìwà rere, nípa ìwà tútù ti ọgbọ́n. 14 Ṣùgbọ́n ̀yin owú kíkorò àti ìjà ọkàn yín, ṣe ṣe féfé, ṣèké òtítọ́. 15 Ọgbọ́n yìí í ṣe èyí ó ti ̀dọ̀ Ọlọ́run , ṣùgbọ́n ti ayé ni, ti ara ni, ti ̀èṣù ni. 16 Nítorí níbi owú òun ìjà gbé , níbẹ̀ ni rúdurùdu àti iṣẹ́ búburú gbogbo .

17 Ṣùgbọ́n ọgbọ́n ó ti òkè jẹ́ mímọ́ àkọ́kọ́, ti àlàáfíà, àti ti ìrẹ̀lẹ̀, í í ṣòro láti bẹ̀, ó kún fún àánú àti fún èso rere, í ṣe ojúsàájú, a máa sọ òtítọ́. 18 Àwọn ó ń ṣiṣẹ́ àlàáfíà a máa gbin èso àlàáfíà àlàáfíà.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-