Publicidade

Compaixão

Por Bíblia Online

A compaixão é o coração de Deus em ação. Ele é compassivo e misericordioso, tardio em irar-se e grande em amor. Somos chamados a refletir essa compaixão no mundo.

baba ti ń ṣe ìyọ́àwọn ọmọ rẹ̀,

bẹ́̀ ni Olúwa ń ṣe ìyọ́àwọn ó bẹ̀rẹ̀,

Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, jẹ́ aláàánú àti Ọlọ́run olójúrere,

Ó lọ́ra láti bínú, Ó pọ̀ ìfẹ́ àti òtítọ́.

Nítorí ìfẹ́ rẹ dára ju ayé lọ,

ètè mi yóò fògo fún .

Nítorí ìfẹ́ Olúwa ó lágbára ni àwa fi ṣègbé,

nítorí ti àánú rẹ í kùnà.

Wọ́n jẹ́ ̀tún àárọ̀;

títóbi ni òdodo rẹ̀.

"Ǹjẹ́ abiyamọ ha le gbàgbé ọmọ ọmú rẹ̀

ó ṣàánú fún ọmọ rẹ̀ ó ti ?

ó tilẹ̀ jẹ́ òun le gbàgbé,

Èmi yóò gbàgbé rẹ!

Kíyèsi i, mo ti kọ ́ àtẹ́lẹwọ́ mi

ògiri rẹ níwájú mi nígbà gbogbo.

Síbẹ̀síbẹ̀ Olúwa fẹ́ síjú àánú ́;

ó dìde láti ṣàánú fún .

Nítorí Olúwa jẹ́ Ọlọ́run ìdájọ́.

Ìbùkún ni fún gbogbo àwọn ó dúró é!

Ta ni Ọlọ́run rẹ̀,

ẹni ó dárí ̀ṣẹ̀ ,

ó fojú fo ìrékọjá èyí tókù ìní rẹ̀?

í dúró nínú ìbínú rẹ̀ láéláé

nítorí òun inú dídùn àánú.

"Èmi o ilé Juda agbára,

èmi o gba ilé Josẹfu ,

èmi ó tún wọn padà

nítorí mo ṣàánú fún wọn,

ó dàbí ẹni èmi ì í ta wọ́n ;

nítorí èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn,

èmi o gbọ́ tiwọn

"Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , Ṣe ìdájọ́ òtítọ́, ṣe àánú àti ìyọ́olúkúlùkù arákùnrin rẹ̀. ṣe ni opó lára tàbí aláìní baba, àlejò, tàbí tálákà; ẹnikẹ́ni nínú yín ṣe gbèrò ibi ọkàn arákùnrin rẹ̀.’

Nítorí náà, àyànfẹ́ Ọlọ́run, ẹni mímọ́ àti olùfẹ́, gbé ọkàn ìyọ́wọ̀, ìṣoore, ìrẹ̀lẹ̀, inú tútù àti sùúrù.

máa ṣoore fún ọmọnìkejì yín, ìyọ́, máa dáríjì ara yín, gẹ́gẹ́ Ọlọ́run nínú Kristi ti dáríjì yín.

Jíjìyà fún ṣíṣe iṣẹ́ rere

Lákòótan, gbogbo yín jẹ́ onínú kan, máa ara yín kẹ́dùn, ìfẹ́ ará, máa ṣe ìyọ́, ni ̀ìrẹ̀lẹ̀.

Ṣùgbọ́n ẹni ó ni ohun ìní ayé, ó ri arákùnrin rẹ̀ ó ṣe aláìní, ó ìlẹ̀kùn ìyọ́rẹ̀ mọ́ ọn, báwo ni ìfẹ́ Ọlọ́run ṣe ń gbé inú rẹ̀?

Ọlọ́run gbogbo ìtùnú

Olùbùkún ni Ọlọ́run, àti Baba Jesu Kristi Olúwa wa, Baba ìyọ́, àti Ọlọ́run ìtùnú gbogbo. Ẹni ń nínú ni gbogbo ìdààmú wa, ki àwa pẹ̀máa tu àwọn ó nínú ìdààmú nínú, nípá ìtùnú náà ti a fi ń àwa fúnra wa nínú láti ̀dọ̀ Ọlọ́run .

Nítorí a olórí àlùfáà ṣàì ba ni kẹ́dùn nínú àìlera wa, ẹni a ti dánwò lọ́gbogbo gẹ́gẹ́ àwa, ṣùgbọ́n òun dẹ́ṣẹ̀.

Àwọn ń yọ̀, máa wọn yọ̀, àwọn ń sọkún, máa wọn sọkún.

Ìkíni ìkẹyìn

àkótán, ará ó gbòóṣe, ṣe àtúnṣe ̀yín, tújúká, jẹ́ onínú kan, máa àlàáfíà, Ọlọ́run ìfẹ́ àti ti àlàáfíà yóò pẹ̀yín.

Seja o primeiro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-