Publicidade

Zacarias 7

Òdodo àti àánú, í ṣe àwẹ̀

1 Ó ṣe ọdún kẹrin Dariusi ọba, ̀rọ̀ Olúwa tọ́ Sekariah ni ọjọ́ kẹrin oṣù Kisleu ń ṣe oṣù kẹsànán. 2 Nígbà wọ́n ènìyàn Beteli rán Ṣareseri àti Regemmeleki, àti àwọn ènìyàn wọn ilé Ọlọ́run láti ojúrere Olúwa. 3 Àti láti àwọn àlùfáà ó ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun, àti àwọn wòlíì sọ̀rọ̀ , "Ṣé èmi ó sọkún oṣù karùn-ún èmi ya ara mi sọ́tọ̀, mo ti ń ṣe láti ọdún mélòó wọ̀nyí ?"

4 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tọ̀ , 5 "Sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, àti fún àwọn àlùfáà , Nígbà ̀yin gbààwẹ̀, ṣọ̀fọ̀ oṣù karùn-ún àti keje, àní fun àádọ́rin ọdún wọ̀nyí, ǹjẹ́ èmi ni ̀yin ha ń gbààwẹ̀ yín fún? 6 Nígbà jẹ, àti nígbà mu, fún ara yín kọ́ ni ̀yin jẹ, àti fún ara yín kọ́ ni ̀yin ? 7 Wọ̀nyí kọ́ ni ̀rọ̀ ti Olúwa ti kígbe láti ̀dọ̀ àwọn wòlíì ìṣáájú , nígbà a ń gbé Jerusalẹmu, ó àlàáfíà, pẹ̀àwọn ìlú rẹ̀ ó i káàkiri, nígbà a ń gbé gúúsù àti pẹ̀tẹ́lẹ̀.’ "

8 ̀rọ̀ Olúwa tọ Sekariah , , 9 "Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , Ṣe ìdájọ́ òtítọ́, ṣe àánú àti ìyọ́olúkúlùkù arákùnrin rẹ̀. 10 ṣe ni opó lára tàbí aláìní baba, àlejò, tàbí tálákà; ẹnikẹ́ni nínú yín ṣe gbèrò ibi ọkàn arákùnrin rẹ̀.’

11 "Ṣùgbọ́n wọ́n kọ̀ láti gbọ́, wọ́n gún èjìká, wọ́n pa ̀yìn , wọ́n di etí wọn, wọn ba à gbọ́. 12 Wọ́n ọkàn wọn òkúta líle, wọn ba à gbọ́ òfin, àti ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti fi ̀rẹ̀ rán nípa ọwọ́ àwọn wòlíì ìṣáájú . Ìbínú ńlá láti ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.

13 " Ó ṣe, gẹ́gẹ́ ó ti kígbe, wọn fẹ́ gbọ́, bẹ́̀ ni wọ́n kígbe, èmi fẹ́ gbọ́,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun . 14 Mo fi ìjì wọn gbogbo orílẹ̀-èdè wọn mọ̀. Ilẹ̀ náà dahoro lẹ́yìn wọn, ẹnikẹ́ni á kọjá tàbí ó padà bọ̀, wọ́n sọ ilẹ̀ ààyò náà dahoro.’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-