Publicidade

Zacarias 10

Olúwa yóò gba Juda

1 béèrè òjò nígbà àrọ̀kúrò ni ọwọ́ Olúwa;

Olúwa o mọ̀nàmọ́,

ó fi ̀pọ̀ òjò fún ènìyàn,

fún olúkúlùkù koríko pápá.

2 Nítorí àwọn òrìṣà sọ̀rọ̀ asán,

àwọn aláfọ̀ṣẹ èké,

wọn rọ àlá èké;

wọ́n ń tu ni nínú lásán,

nítorí náà àwọn ènìyàn náà ṣáko lọ àgùntàn,

a ṣẹ wọn níṣẹ̀́, nítorí Olùṣọ́-àgùntàn .

3 "Ìbínú mi ru àwọn darandaran,

èmi o jẹ àwọn olórí

nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti bẹ agbo rẹ̀,

ilé Juda ,

yóò fi wọn ṣe ẹṣin rẹ̀ dáradára ogun.

4 Láti ̀dọ̀ rẹ̀ ni òkúta igun ilé ti jáde ,

láti ̀dọ̀ rẹ ni èèkàn àgọ́ ,

láti ̀dọ̀ rẹ ni ọrún ogun ,

láti ̀dọ̀ rẹ ni àwọn akóniṣiṣẹ́ gbogbo .

5 Gbogbo wọn yóò dàbí ọkùnrin

alágbára ni ogun ń tẹ àwọn ̀wọn mọ́lẹ̀ ìgboro, wọn ó jagun,

nítorí Olúwa pẹ̀wọn,

wọn ó dààmú àwọn ń gun ẹṣin.

6 "Èmi o ilé Juda agbára,

èmi o gba ilé Josẹfu ,

èmi ó tún wọn padà

nítorí mo ṣàánú fún wọn,

ó dàbí ẹni èmi ì í ta wọ́n ;

nítorí èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn,

èmi o gbọ́ tiwọn

7 Efraimu yóò ṣe alágbára,

ọkàn wọn yóò yọ̀ bi ẹni nípa ọtí wáìnì:

àní àwọn ọmọ wọn yóò í,

wọn o yọ̀, inú wọn ó dùn nínú Olúwa.

8 Èmi ó kọ wọn, èmi ó ṣà wọ́n jọ;

nítorí èmi wọ́n padà;

wọn ó pọ̀ i gẹ́gẹ́

wọ́n ń pọ̀ í .

9 ó tilẹ̀ jẹ́ mo wọn káàkiri orílẹ̀-èdè:

síbẹ̀ wọn ó rántí mi ni ilẹ̀ jíjìn;

wọn ó gbé pẹ̀àwọn ọmọ wọn,

wọn ó tún padà.

10 Èmi ó tún wọn padà kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀,

èmi ó ṣà wọn jọ kúrò ni ilẹ̀ Asiria.

Èmi ó wọn ilẹ̀ Gileadi àti Lebanoni;

a yóò ààyè fún wọn ó ti yẹ.

11 Wọn yóò la Òkun wàhálà ,

yóò bori rírú omi nínú Òkun,

gbogbo ibú odò ni yóò gbẹ,

a ó rẹ ìgbéraga Asiria sílẹ̀,

̀aládé Ejibiti yóò lọ kúrò.

12 Èmi ó wọn agbára nínú Olúwa;

wọn ó rìn sókè rìn sódò ni orúkọ rẹ̀,"

ni Olúwa .

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-