Publicidade

Sinais do fim dos tempos

Por Bíblia Online

A Bíblia descreve sinais que precederão a volta de Jesus. Guerras, falsos mestres, sinais cósmicos e a pregação do evangelho a todas as nações — tudo aponta para o fim dos tempos.

Sinais proféticos

Este evangelho do Reino será pregado em todo o mundo e então virá o fim. Os sinais dos últimos tempos já se manifestam.

A ó wàásù ìyìnrere nípa ìjọba náà yìí gbogbo ayé , láti ṣe ̀fún gbogbo orílẹ̀-èdè, nígbà náà ni òpin yóò .

"Lójúkan náà, lẹ́yìn ìpọ́njú ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì,

" ni oòrùn yóò ṣókùnkùn,

òṣùpá yóò fi ìmọ́lẹ̀ rẹ hàn;

àwọn ìràwọ̀ ojú ̀run yóò sílẹ̀,

agbára ojú ̀run ni a ó tìtì.

"Nígbà náà ni àmì Ọmọ Ènìyàn yóò fi ara hàn ̀run, nígbà náà ni gbogbo ̀ayé yóò káàánú, wọn yóò Ọmọ Ènìyàn yóò máa ti ojú ̀run bọ̀ ti òun ti ògo àti agbára ńlá. Yóò rán àwọn angẹli rẹ̀ jáde pẹ̀ohùn ìpè ńlá, wọn yóò gbogbo àwọn àyànfẹ́ rẹ̀ láti orígun mẹ́rẹ̀̀rin ayé àti ̀run jọ.

"Nítorí náà, múra sílẹ̀, nítorí mọ ọjọ́ Olúwa yín yóò . Ṣùgbọ́n, mọ èyí , baálé ilé ìbá mọ wákàtí náà olè yóò , ìbá máa ṣọ́, òun ti jẹ́ a wọ ilé rẹ̀. Nítorí náà, gbọdọ̀ ìmúrasílẹ̀, nítorí wákàtí àìròtẹ́lẹ̀ ni dídé Ọmọ Ènìyàn yóò jẹ́.

kọ́ wọn láti máa kíyèsi ohun gbogbo èyí mo ti pàṣẹ fún yín. Nítorí èmi pẹ̀yín ìgbà gbogbo títí ó fi òpin ayé."

Ọjọ́ àti wákàtí a mọ̀

"Ṣùgbọ́n ẹni ó mọ ọjọ́ tàbí wákàtí nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹlẹ̀. Àwọn angẹli ̀run pàápàá mọ̀. Àní, èmi pẹ̀mọ̀ ́n, ṣe baba nìkan.

Os últimos dias

Nos últimos dias virão tempos difíceis, homens amantes de si mesmos. Mas derramarei o meu Espírito sobre toda a carne.

Ìwà àwọn ènìyàn ni ọjọ́ ìkẹyìn

Ṣùgbọ́n èyí ni o mọ̀ , ìkẹyìn ọjọ́ ìgbà ewu yóò . Nítorí àwọn ènìyàn yóò jẹ́ olùfẹ́ ti ara wọn, olùfẹ́ owó, afọ́nnu, agbéraga, asọ̀rọ̀ búburú, aṣàìgbọràn òbí, aláìlọ́pẹ́, aláìmọ́. Aláìnífẹ̀́, aláìlèdáríjì, abanijẹ́, aláìlè-kó-aràwọn-níjánu, òǹrorò, aláìnífẹ̀́ ohun rere, oníkúpani, alágídí, ọlọ́kàn gíga, olùfẹ́ fàájì ju olùfẹ́ Ọlọ́run lọ. Àwọn wọn àfarawé ìwà-bí-Ọlọ́run, ṣùgbọ́n wọn sẹ́ agbára rẹ̀; yẹra kúrò lọ́dọ̀ àwọn wọ̀nyí pẹ̀.

"Ọlọ́run , ìkẹyìn ọjọ́,

Èmi yóò nínú ̀jáde sára ènìyàn gbogbo,

àwọn ọmọ yín ọkùnrin àti àwọn ọmọ yín obìnrin yóò máa sọtẹ́lẹ̀

àwọn ̀dọ́mọkùnrin yín yóò máa ríran,

àwọn arúgbó yín yóò máa àlá,

àti sára àwọn ọmọ ̀dọ̀ mi ọkùnrin àti sára àwọn ọmọ ̀dọ̀ mi obìnrin,

ni Èmi yóò nínú ̀mi jáde ni ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì:

wọn yóò máa sọtẹ́lẹ̀.

Èmi yóò fi iṣẹ́ ìyanu hàn lójú ̀run,

àti àwọn àmì nísàlẹ̀ ilẹ̀;

̀jẹ̀ àti iná àti rírú èéfín;

A ó sọ oòrùn di òkùnkùn,

àti òṣùpá di ̀jẹ̀,

ọjọ́ ńlá àti ọjọ́ ológo Olúwa .

Yóò ṣe, ẹnikẹ́ni ó pe

orúkọ Olúwa ni a ó gbàlà.

Ọjọ́ Olúwa

"Yóò ṣe níkẹyìn ọjọ́,

èmi yóò nínú ̀ara ènìyàn gbogbo;

àwọn ọmọ yín ọkùnrin àti àwọn ọmọ yín obìnrin yóò máa sọtẹ́lẹ̀,

àwọn arúgbó yín yóò máa àlá,

àwọn ̀dọ́mọkùnrin yín yóò máa ríran.

Àti pẹ̀ara àwọn ọmọ ̀dọ̀ ọkùnrin,

àti ara àwọn ọmọ ̀dọ̀ obìnrin,

èmi yóò ̀jáde ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì.

Ìgbà ìkẹyìn

"àkókò náà, ni Mikaeli, ọmọ-aládé ńlá, ẹni o ń dáàbò bo àwọn ènìyàn an rẹ̀ yóò dìde. Àkókò ìpọ́njú yóò , irú èyí ì ṣẹlẹ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè títí di àkókò náà. Ṣùgbọ́n àkókò náà àwọn ènìyàn rẹ̀, gbogbo àwọn a ti orúkọ wọn nínú ìwé ni a ó gbàlà. ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ó sùn nínú erùpẹ̀ ilẹ̀ ni yóò : àwọn mìíràn ìyè àìnípẹ̀kun, àwọn tókù ìtìjú àti ̀gàn àìnípẹ̀kun. Àwọn ó jẹ́ ọlọ́gbọ́n yóò máa tàn ìmọ́lẹ̀ ̀run, àti àwọn ó ń tọ́nisọ́òdodo, yóò máa tàn ìràwọ̀ láé àti láéláé.

Esperança e prontidão

O dia do Senhor virá como ladrão. Mas nós não somos das trevas — estejamos sóbrios, vigiliando e esperando.

Gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa, àwa ó láààyè, a lẹ́yìn de à ti Olúwa, ó ti ó , yóò ṣáájú àwọn ó sùn láti pàdé rẹ̀. Nítorí , Olúwa fúnra rẹ̀ yóò sọ̀kalẹ̀ láti ̀run , pẹ̀ariwo àṣẹ ńlá àti ohùn àwọn angẹli ti àwọn angẹli ti àwọn ti ìpè Ọlọ́run, àwọn òkú nínú Kristi yóò kọ́kọ́ jíǹde. Nígbà náà ni a ó gba àwa ó láààyè sókè nínú àwọsánmọ̀ láti ọwọ́ Olúwa. A ó pẹ̀rẹ̀ títí láéláé. Nítorí náà, tu ara yín nínú, máa gba ara yín níyànjú pẹ̀̀rọ̀ wọ̀nyí.

Nítorí náà, kíyèsára yín ṣe sùn àwọn ẹlòmíràn. máa ṣọ́máa pa ara yín mọ́. Nítorí àwọn wọ́n ń sùn, a máa sùn òru, àwọn ẹni ń mu àmupara, a máa un òru. Ṣùgbọ́n àwa jẹ́ ti ìmọ́lẹ̀, jẹ́ a pa ara wa mọ́, gbígbé ìgbàgbọ́ wọ̀ àti ìfẹ́ ìgbàyà ni òru àti ìrètí ìgbàlà àṣíborí. Nítorí , Ọlọ́run yàn wa láti da ìbínú rẹ̀ gbígbóná orí wa, ṣùgbọ́n ó yàn láti gbà nípasẹ̀ Olúwa wa, Jesu Kristi.

"Ṣùgbọ́n máa kíyèsára yín, ọkàn yín ṣe kún fún wọ̀bìà, àti fún ọtí àmupara, àti fún àníyàn ayé yìí, ọjọ́ náà yóò fi yín lójijì ìkẹ́kùn. Nítorí bẹ́̀ ni yóò gbogbo àwọn ń gbé orí gbogbo ilẹ̀ ayé. Ǹjẹ́ máa ṣọ́, máa gbàdúrà nígbà gbogbo, ba à la gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹlẹ̀, dúró níwájú Ọmọ Ènìyàn."

Ṣùgbọ́n, olùfẹ́, ṣe gbàgbé ohun kan yìí, ọjọ́ kan lọ́dọ̀ Olúwa ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún ni ó , àti ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún ọjọ́ kan. Olúwa fi ìlérí rẹ̀ jáfara, àwọn ẹlòmíràn ti ka ìjáfara ; ṣùgbọ́n ó ń sùúrù fún yín nítorí fẹ́ ẹnikẹ́ni ṣègbé, ṣe gbogbo ènìyàn ìrònúpìwàdà.

Ṣùgbọ́n ọjọ́ Olúwa ń bọ̀ olè òru; nínú èyí àwọn ̀run yóò kọjá lọ pẹ̀ariwo ńlá, àti àwọn ìmọ́lẹ̀ ojú ̀run yóò ti inú ooru gbígbóná gidigidi di yíyọ́, ayé àti àwọn iṣẹ́ ó nínú rẹ̀ yóò jóná túútúú.

Ǹjẹ́ gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò ti yọ́ bẹ́̀, irú ènìyàn wo ni ̀yin ìbá jẹ́ nínú ìwà mímọ́ gbogbo àti ìwà-bí-Ọlọ́run. máa retí, máa múra gírí de dídé ọjọ́ Ọlọ́run, nítorí èyí àwọn ̀run yóò gbiná, wọn yóò di yíyọ́, àwọn ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ yóò ti inú ooru gbígbóná gidigidi di yíyọ́. Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ ìlérí rẹ̀, àwa ń retí àwọn ̀run tuntun àti ayé títún nínú èyí òdodo ń gbé.

Kíyèsi í, ohun ìjìnlẹ̀ ni mo sọ fún un yín, gbogbo yóò sùn, ṣùgbọ́n gbogbo a ó paláradà. Lọ́gán, ni ìṣẹ́kan, nígbà ìpè ìkẹyìn: nítorí ìpè yóò dún, a ó àwọn òkú dìde àìdíbàjẹ́, a ó pa láradà.

Àwọn ọrun tuntun àti ayé tuntun

"Kíyèsi i, Èmi yóò

àwọn ̀run tuntun àti ayé tuntun.

A yóò rántí ohun àtẹ̀yìnwá mọ́,

tàbí wọn ọkàn.

Ṣùgbọ́n yọ̀ inú yín dùn títí láé

nínú ohun èmi yóò ,

nítorí èmi yóò Jerusalẹmu láti jẹ́ ohun ìdùnnú

àti àwọn ènìyàn rẹ̀, ohun ayọ̀.

Èmi yóò ṣe àjọyọ̀ lórí Jerusalẹmu

n ó inú dídùn nínú àwọn ènìyàn mi;

ariwo ẹkún àti igbe

ni a yóò gbọ́ nínú rẹ̀ mọ́.

Ọjọ́ Olúwa n bọ

"Dájúdájú, ọjọ́ náà ń bọ̀; yóò máa bi iná ìléru. Gbogbo àwọn agbéraga, àti gbogbo àwọn olùṣe búburú yóò dàbí àgékù koríko: ọjọ́ náà ń bọ̀ yóò si wọn run," ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "Ti ki yóò fi gbòǹgbò kan tàbí ̀ka kan fún wọn. Ṣùgbọ́n fún ̀yin ó bẹ̀orúkọ mi, oòrùn òdodo yóò yọ, pẹ̀ìmúláradá ni ìyẹ́ apá rẹ̀. ̀yin yóò jáde lọ, ̀yin yóò máa fún ayọ̀ bi àwọn ẹgbọrọ màlúù a sílẹ̀ lórí ìso.

Jerusalẹmu tuntun

Mo ̀run tuntun kan àti ayé tuntun kan, nítorí ̀run ti ìṣáájú àti ayé ìṣáájú ti kọjá lọ; Òkun ṣí mọ́. Mo ìlú mímọ́, Jerusalẹmu tuntun ń ti ̀run sọ̀kalẹ̀ láti ̀dọ̀ Ọlọ́run, a ti múra sílẹ̀ ìyàwó a ṣe lọ́ṣọ̀́ fún ọkọ rẹ̀. Mo gbọ́ ohùn ńlá kan láti orí ìtẹ́ náà , ń , "Kíyèsi i, àgọ́ Ọlọ́run pẹ̀àwọn ènìyàn, òun ó máa wọn gbé, wọn ó máa jẹ́ ènìyàn rẹ̀, àti Ọlọ́run tìkára rẹ̀ yóò pẹ̀wọn, yóò máa jẹ́ Ọlọ́run wọn. Ọlọ́run yóò nu omijé gbogbo kúrò ni ojú wọn; yóò ṣí ikú mọ́, tàbí ̀fọ̀, tàbí ẹkún, bẹ́̀ ni yóò ìrora mọ́, nítorí ohun àtijọ́ kọjá lọ."

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-