Pular para o conteúdo
Publicidade

Humildade

Por Bíblia Online

A humildade é o caminho da honra verdadeira. Deus resiste aos soberbos, mas dá graça aos humildes. Jesus lavou os pés dos discípulos e nos ensinou que o maior é aquele que serve.

Humilhar-se diante de Deus

Humilhai-vos diante do Senhor e Ele vos exaltará. Quem se humilha será exaltado, e quem se exalta será humilhado.

rẹ ara yín sílẹ̀ níwájú Olúwa, òun ó gbé yín ga.

Nítorí náà, rẹ ara yin sílẹ̀ lábẹ́ ọwọ́ agbára Ọlọ́run, òun gbe yín ga lákokò.

àwọn ènìyàn, a fi orúkọ mi , wọ́n rẹ ara wọn sílẹ̀, wọ́n gbàdúrà, wọ́n ojú mi, wọ́n kúrò nínú ̀búburú wọn, nígbà náà, èmi yóò gbọ́ láti ̀run, èmi yóò dárí ̀ṣẹ̀ wọn wọ́n èmi yóò wo ilẹ̀ wọn sàn.

Rere àti ẹni ìdúró ṣinṣin Olúwa:

nítorí náà, ó kọ́ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ni ̀náà.

Ó ṣe amọ̀àwọn onírẹ̀lẹ̀ ni ohun ó dára,

ó kọ́ àwọn onírẹ̀lẹ̀ ̀rẹ̀.

Ìgbéraga ènìyàn a máa sọ ́ di ẹni ilẹ̀

ṣùgbọ́n onírẹ̀lẹ̀ ènìyàn a máa gba iyì kún iyì.

Ṣáájú ìṣubú ọkàn ènìyàn a kọ́kọ́ máa gbéraga,

ṣùgbọ́n ìrẹ̀lẹ̀ ni ó máa ń ṣáájú ọlá.

Humildade como virtude

Considerai os outros como superiores a vós mesmos. Revesti-vos de humildade, mansidão e paciência no trato uns com os outros.

ṣe ohunkóhun nínú ìlépa ara tàbí ògo asán, ṣùgbọ́n ìrẹ̀lẹ̀ ọkàn olúkúlùkù ro àwọn ẹlòmíràn ẹni ti ó sàn ju òun lọ.

Ṣùgbọ́n ògo ni fún Ọlọ́run àti Baba wa láé àti láéláé. Àmín.

Nítorí náà, àyànfẹ́ Ọlọ́run, ẹni mímọ́ àti olùfẹ́, gbé ọkàn ìyọ́wọ̀, ìṣoore, ìrẹ̀lẹ̀, inú tútù àti sùúrù.

Pẹ̀ìrẹ̀lẹ̀ gbogbo àti inú tútù, pẹ̀ìpamọ́ra, máa fi ìfẹ́ faradà fún ẹnìkejì yín.

Nítorí a ti yín òmìnira, ará kìkì ṣe lo òmìnira yín àǹfààní sípa ti ara, ṣùgbọ́n máa fi ìfẹ́ sin ọmọnìkejì yín.

Jíjìyà fún ṣíṣe iṣẹ́ rere

Lákòótan, gbogbo yín jẹ́ onínú kan, máa ara yín kẹ́dùn, ìfẹ́ ará, máa ṣe ìyọ́, ni ̀ìrẹ̀lẹ̀.

̀ṣọ́ yín ṣe jẹ́ ̀ṣọ́ òde, irun dídì, àti wúrà lílò, tàbí ti aṣọ wíwọ̀; ṣùgbọ́n ó jẹ́ ẹni ó fi ara sin ọkàn, nínú ̀ṣọ́ àìdíbàjẹ́ ti ̀ìrẹ̀lẹ̀ àti ̀tútù, èyí i ṣe iyebíye níwájú Ọlọ́run.

O exemplo de Jesus

Aprendei de mim, que sou manso e humilde de coração. O maior entre vós seja o que serve — esse é o caminho do Reino.

gbé àjàgà mi wọ̀. kọ́ ̀kọ́ lọ́dọ̀ mi nítorí onínútútù àti onírẹ̀lẹ̀ ọkàn ni èmi, ̀yin yóò ri ìsinmi fún ọkàn yín. Nítorí àjàgà mi rọrùn ẹrù mi fúyẹ́."

"Nítorí náà, nígbà ti ́ ti ń fún aláìní, ṣe fi fèrè kéde rẹ̀, gẹ́gẹ́ àwọn àgàbàgebè ti í ṣe Sinagọgu àti ìta gbangba; àwọn ènìyàn le yìn wọ́n. Lóòótọ́ ni mo fún yín, wọ́n ti gba èrè wọn kíkún.

Ó jókòó, ó àwọn méjìlá náà, ó sọ fún wọn , "ẹnikẹ́ni fẹ́ ṣe ẹni ìṣáájú, òun ni yóò ṣe ẹni ìkẹyìn gbogbo wọn. Ó láti jẹ́ ìránṣẹ́ gbogbo ènìyàn."

Ó fún wọn , "Ẹnikẹ́ni ó gba ọmọdé yìí nítorí orúkọ mi, ó gbà : àti ẹnikẹ́ni ó gbà , ó gba ẹni ó rán mi: nítorí ẹni ó kéré nínú gbogbo yín, òun náà ni yóò pọ̀."

Èrè ìrẹ̀lẹ̀ àti ìbẹ̀Olúwa ni ọrọ̀ ọlá, àti ìyè.

Ìbẹ̀Olúwa kọ́ ènìyàn ọgbọ́n,

ìrẹ̀lẹ̀ ni ó máa ń ṣáájú ọlá.

Nígbà ìgbéraga , nígbà náà ni ìdójútì ,

ṣùgbọ́n pẹ̀ìrẹ̀lẹ̀ ni ọgbọ́n ń .

Humildade verdadeira

O que se exige de ti? Praticar a justiça, amar a misericórdia e andar humildemente com teu Deus.

Ó ti fihàn ́, ìwọ ènìyàn, ohun ó dára,

àti ohun Olúwa ń béèrè lọ́wọ́ rẹ?

ṣe láti ṣe òtítọ́, o fẹ́ràn àánú,

àti o rìn ìrẹ̀lẹ̀ pẹ̀Ọlọ́run rẹ̀.

Àwọn òfin fún agbo ilé Kristi

̀yin aya, máa tẹríba fún àwọn ọkọ yín, gẹ́gẹ́ ó ti yẹ nínú Olúwa.

̀yin ọkọ, máa fẹ́ràn àwọn aya yín, ṣe korò wọn.

máa inú kan náà ara yín. ṣe gbéraga, ṣùgbọ́n tẹ̀àwọn onírẹ̀lẹ̀. ṣe jẹ́ ọlọ́gbọ́n ojú ara yín.

Àti àwọn ohun ayé ìyìn, àti àwọn ohun a kẹ́gàn, ni Ọlọ́run ti yàn, àní àwọn ohun , láti sọ àwọn ohun ó di asán. Nítorí ó ba à ẹnìkan yóò ṣògo níwájú rẹ̀.

Oríṣìí ọgbọ́n méjì

Ta ni ó gbọ́n ó ìmọ̀ nínú yín? jẹ́ ó fi iṣẹ́ rẹ̀ hàn nípa ìwà rere, nípa ìwà tútù ti ọgbọ́n.

Seja o primeiro