Publicidade

Provérbios 11

1 Olúwa kórìíra òsùwọ̀n èké,

ṣùgbọ́n òsùwọ̀n òtítọ́ jẹ́ inú dídùn un rẹ̀.

2 Nígbà ìgbéraga , nígbà náà ni ìdójútì ,

ṣùgbọ́n pẹ̀ìrẹ̀lẹ̀ ni ọgbọ́n ń .

3 Òtítọ́ inú ẹni dídúró ṣinṣin ń ṣe amọ̀rẹ̀,

ṣùgbọ́n aláìṣòótọ́ yóò parun nípasẹ̀ àìṣòótọ́ wọn.

4 ̀rọ̀ níláárí ọjọ́ ìbínú,

ṣùgbọ́n òdodo a máa gbani lọ́wọ́ ikú.

5 Òdodo aláìlẹ́gàn ṣe ̀tààrà fún wọn,

ṣùgbọ́n ìwà búburú ènìyàn búburú yóò á lulẹ̀.

6 Òdodo ẹni ìdúró ṣinṣin gbà wọ́n ,

ṣùgbọ́n ìdẹ̀kùn ètè búburú aláìṣòótọ́.

7 Nígbà ènìyàn búburú , ìrètí rẹ̀ a parun;

gbogbo ohun ń fojú ṣọ́fún nípa agbára rẹ̀ ṣófo.

8 A gba olódodo kúrò lọ́wọ́ ibi dípò o rẹ̀,

ibi sórí ènìyàn búburú.

9 Aláìmọ Ọlọ́run fi ẹnu rẹ̀ ba aládùúgbò rẹ̀ jẹ́,

ṣùgbọ́n nípasẹ̀ ìmọ̀ olódodo àsálà.

10 Nígbà olódodo ń gbèrú, ìlú a yọ̀;

nígbà ènìyàn búburú parun, ariwo ayọ̀ gba ìlú kan.

11 Nípasẹ̀ ìbùkún, olódodo a gbé ìlú ga:

ṣùgbọ́n nípasẹ̀ ẹnu ènìyàn búburú, a pa ìlú run.

12 Ẹni gbọ́n fojú kékeré wo aládùúgbò rẹ̀

ṣùgbọ́n ẹni ó òye pa ẹnu rẹ̀ mọ́.

13 Olófòófó àṣírí ìkọ̀kọ̀

ṣùgbọ́n ẹni ṣe é gbẹ́kẹ̀a pa àṣírí mọ́.

14 Nítorí àìní ìtọ́sọ́orílẹ̀-èdè ṣubú

ṣùgbọ́n nípasẹ̀ ̀pọ̀lọpọ̀ olùbádámọ̀ràn ìṣẹ́gun dájú.

15 Ẹni ó ṣe onígbọ̀wọ́ fún àlejò yóò ìyọnu,

ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó kọ̀ láti ṣe onígbọ̀wọ́ yóò láìléwu.

16 Obìnrin oníwà rere gba ìyìn

ṣùgbọ́n alágbára aláìbìkítà ènìyàn gba ọrọ̀ nìkan.

17 Ènìyàn rere ń ṣe ara rẹ̀ lóore

ṣùgbọ́n ènìyàn ìkà ń ìyọnu sórí ara rẹ̀.

18 Ènìyàn búburú gba èrè ìtànjẹ

ṣùgbọ́n ẹni fúnrúgbìn òdodo yóò gba èrè dájú.

19 Olódodo tòótọ́ ìyè

ṣùgbọ́n ẹni ń lépa ibi e ibi ikú ara rẹ̀.

20 Olúwa kórìíra àwọn ènìyàn ọlọ́kàn búburú

ṣùgbọ́n ó inú dídùn àwọn ̀wọn lábùkù.

21 Mọ èyí dájú , ènìyàn búburú yóò lọ láìjìyà,

ṣùgbọ́n àwọn olódodo yóò lọ láìjìyà.

22 òrùka wúrà imú ẹlẹ́dẹ̀

ni arẹwà obìnrin lọ́gbọ́n.

23 Ìfẹ́ inú olódodo yóò yọrí ohun rere

ṣùgbọ́n ìrètí ènìyàn búburú yóò yọrí ìbínú.

24 Ènìyàn kan ń fún ni lọ́fẹ̀́, síbẹ̀ ó ń i;

òmíràn ń háwọ́ ju ó ti yẹ ṣùgbọ́n ó di aláìní.

25 Ẹni ń ṣoore yóò máa gbèrú i;

ẹni ó tu ẹlòmíràn lára yóò ìtura.

26 Àwọn ènìyàn a ṣẹ́ èpè ènìyàn ń oúnjẹ pamọ́

ṣùgbọ́n ìbùkún a máa sórí ẹni ó ṣetán láti .

27 Ẹni ń lépa ohun rere yóò ohun rere

ṣùgbọ́n ibi yóò ẹni ń lépa ibi.

28 Ẹnikẹ́ni ó gbẹ́kẹ̀ọrọ̀ rẹ̀ yóò ṣubú;

ṣùgbọ́n olódodo yóò gbilẹ̀ i koríko tútù.

29 Ẹni ó ń ìdààmú ìdílé rẹ̀ yóò jogún afẹ́fẹ́ lásán

aláìgbọ́n yóò máa ṣe ìránṣẹ́ fún ọlọ́gbọ́n.

30 Èso òdodo ni igi ìyè

ẹni ó jèrè ọkàn jẹ́ ọlọ́gbọ́n.

31 àwọn olódodo gba ìpín wọn lórí ilẹ̀ ayé

mélòó mélòó ni ènìyàn búburú àti àwọn dẹ́ṣẹ̀!

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-