Publicidade

2 Crônicas 7

Ìyàsímímọ́ ilé Olúwa

1 Nígbà Solomoni ti parí àdúrà, iná sọ̀kalẹ̀ láti ̀run ó ẹbọ sísun àti ẹbọ, ògo Ọlọ́run kún ilé Olúwa. 2 Àwọn àlùfáà le wo ilé Olúwa náà nítorí ògo Olúwa kún un. 3 Nígbà gbogbo àwọn ọmọ Israẹli iná ó ń sọ̀kalẹ̀ àti ògo Olúwa lórí ilé Olúwa náà, wọ́n kúnlẹ̀ lórí eékún wọn pẹ̀ojú ni dídàbolẹ̀, wọ́n sin Olúwa, wọ́n fi ìyìn fún Olúwa ,

"Nítorí ó dára;

àánú rẹ̀ dúró títí láéláé."

4 Nígbà náà ọba àti gbogbo àwọn ènìyàn ẹbọ níwájú Olúwa. 5 Ọba Solomoni ẹbọ ti ẹgbẹ̀rún méjìlélógún (22,000), orí màlúù àti àgùntàn àti ̀kẹ́ mẹ́(120,000) àgùntàn àti ẹranko. Bẹ́̀ ni ọba àti gbogbo àwọn ènìyàn ya ilé Ọlọ́run mímọ́. 6 Àwọn àlùfáà dúró ààyè wọn, gẹ́gẹ́ àwọn ọmọ Lefi ti ṣe pẹ̀ohun èlò orin Olúwa, ọba Dafidi ti ṣe fún ìyìn Olúwa àti á nígbà ó dúpẹ́, , "Àánú rẹ̀ dúró láéláé," níwájú àwọn ọmọ Lefi, àwọn àlùfáà fọn ìpè, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli dúró.

7 Solomoni àgbàlá níwájú ilé Olúwa sọ́tọ̀, níbẹ̀ ni ó ti ṣe ìrúbọ ẹbọ sísun àti ̀ẹbọ àlàáfíà, nítorí pẹpẹ idẹ ó ti ṣe gba ẹbọ sísun, àti ọrẹ oúnjẹ, àti ̀náà.

8 Bẹ́̀ ni Solomoni ṣe àsè àkókò náà fún ọjọ́ méje àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli pẹ̀rẹ̀ àti ìjọ ènìyàn ńlá, àwọn ènìyàn láti Lebo-Hamati títí odò Ejibiti. 9 ọjọ́ kẹjọ, wọ́n pe ìjọ ènìyàn jọ nítorí wọ́n pe àpèjẹ ìyàsímímọ́ ti orí pẹpẹ fún ọjọ́ méje àti àsè náà fún ọjọ́ méje i. 10 ọjọ́ kẹtàlélógún oṣù keje, ó rán àwọn ènìyàn padà ilé wọn, pẹ̀ayọ̀ àti ìdùnnú nínú wọn fún ohun rere Olúwa ti ṣe fún Dafidi àti Solomoni, àti fún àwọn ènìyàn Israẹli.

Olúwa fi ara han Solomoni

11 Nígbà Solomoni ti parí ilé Olúwa àti ibi ilé ọba, nígbà ó ti ṣe àṣeyọrí láti gbé jáde gbogbo ohun ó lọ́kàn láti ṣe nínú ilé Olúwa àti nínú ilé òun tìkára rẹ̀, 12 Olúwa farahàn Solomoni òru ó :

"Èmi ti gbọ́ àdúrà rẹ mo ti yàn ibí yìí fún ara mi gẹ́gẹ́ ilé fún ẹbọ.

13 "Nígbà mo ̀run ó ma à òjò, tàbí láti pàṣẹ fún eṣú láti jẹ ilẹ̀ náà run tàbí rán àjàkálẹ̀-ààrùn àárín àwọn ènìyàn mi, 14 àwọn ènìyàn, a fi orúkọ mi , wọ́n rẹ ara wọn sílẹ̀, wọ́n gbàdúrà, wọ́n ojú mi, wọ́n kúrò nínú ̀búburú wọn, nígbà náà, èmi yóò gbọ́ láti ̀run, èmi yóò dárí ̀ṣẹ̀ wọn wọ́n èmi yóò wo ilẹ̀ wọn sàn. 15 Nísinsin yìí, ojú mi yóò etí mi yóò , àdúrà ọrẹ níbí yìí. 16 Èmi ti yàn, èmi ti ya ilé yìí mímọ́ bẹ́̀ ni orúkọ mi ó le níbẹ̀ títí láéláé.

17 "ti ìwọ rìn níwájú mi gẹ́gẹ́ Dafidi baba rẹ ti ṣe, o ṣe gbogbo ohun mo paláṣẹ, ìwọ ṣe àkíyèsí àṣẹ mi láti ̀run, 18 Èmi yóò fi ìdí ìtẹ́ ìjọba rẹ múlẹ̀, gẹ́gẹ́ mo ti ṣe pẹ̀Dafidi baba rẹ nígbà mo a májẹ̀, ìwọ fẹ́ ẹnìkan láti ṣe alákòóso lórí Israẹli.

19 "Ṣùgbọ́n ìwọ yípadà o kọ òfin mi sílẹ̀ àti àṣẹ mo ti fi fún yín lọ sókè láti lọ sin ọlọ́run mìíràn bọ wọ́n, 20 nígbà náà ni èmi yóò fa Israẹli tu kúrò láti ilẹ̀ mi, èyí èmi ti fi fún wọn, èmi yóò kọ̀ ilé náà sílẹ̀ èyí èmi ti sọ́tọ̀ fún orúkọ mi, èmi yóò fi ṣe ̀rọ̀ òwe, n ó fi ṣe ẹlẹ́láàrín gbogbo ènìyàn, 21 àti gbogbo àyíká ilé yìí nísinsin yìí, bẹ́̀ ni yóò di ohun ìtànjẹ; gbogbo àwọn ó kọjá níbẹ̀ ni yóò jáláyà, wọn yóò , ni ó Olúwa ṣe irú èyí ilẹ̀ àti ilé yìí?22 Àwọn ènìyàn yóò dáhùn , Nítorí wọ́n ti kọ̀ Olúwa sílẹ̀, Ọlọ́run baba wọn ẹni ó wọn jáde láti Ejibiti , wọ́n ti fi ọwọ́ gba ọlọ́run mìíràn mọ́ra, wọ́n bọ wọ́n, bẹ́̀ ni wọ́n ń sìn wọ́n, ìdí nìyí ó fi gbogbo ìjàǹbá náà sórí wọn.’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-