Pular para o conteúdo
Publicidade

O juízo final

Por Bíblia Online

O juízo final é a conclusão da história humana. Todos os seres humanos comparecerão diante do trono de Deus para o julgamento eterno — os salvos para a vida, os ímpios para a condenação.

O grande trono branco

Vi um grande trono branco e os mortos diante de Deus. Os livros foram abertos e cada um foi julgado segundo as suas obras.

Àwọn òkú gba ìdájọ́

Mo ìtẹ́ funfun ńlá kan, àti ẹni ó jókòó lórí rẹ̀, níwájú ẹni ayé àti ̀run lọ; a ààyè fún wọn mọ́. Mo àwọn òkú, àti èwe àti àgbà, wọn dúró níwájú ìtẹ́; a ṣí àwọn ìwé sílẹ̀; a ṣí àwọn ìwé mìíràn kan sílẹ̀ í ṣe ìwé ìyè: a ṣe ìdájọ́ fún àwọn òkú láti inú ohun a ti kọ sínú àwọn ìwé náà, gẹ́gẹ́ iṣẹ́ wọn. Òkun jọ̀wọ́ àwọn òkú ń bẹ nínú rẹ̀ lọ́wọ́; àti òkú àti ipò òkú jọ̀wọ́ òkú ó nínú wọn pẹ̀: a ṣe ìdájọ́ wọn, olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ wọn. Àti ikú àti ipò òkú ni a sọ sínú adágún iná. Èyí ni ikú kejì. a ẹnikẹ́ni a kọ orúkọ rẹ̀ sínú ìwé ìyè, a ó sọ ́ sínú adágún iná.

Ìkádìí: Ìpeni àti ìkìlọ̀

"Kíyèsi i, èmi ń bọ̀ kánkán; èrè ń bẹ pẹ̀mi, láti sán fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀ yóò .

Ìkádìí: Ìpeni àti ìkìlọ̀

"Kíyèsi i, èmi ń bọ̀ kánkán; èrè ń bẹ pẹ̀mi, láti sán fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀ yóò . Èmi ni Alfa àti Omega, ẹni ìṣáájú àti ẹni ìkẹyìn, ìpilẹ̀ṣẹ̀ àti òpin.

Ìdájọ́ níwájú ẹni ìgbàanì

"mo ṣe ń ,

"a gbé ìtẹ́ ọba kan kalẹ̀,

ẹni ìgbàanì jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀.

Aṣọ rẹ̀ funfun ̀gbọ̀n òwú;

irun orí rẹ̀ funfun òwú,

ìtẹ́ ọba rẹ̀ ọwọ́ iná.

Àwọn kẹ̀kẹ́ rẹ ń i iná.

Ìdájọ́ níwájú ẹni ìgbàanì

"mo ṣe ń ,

"a gbé ìtẹ́ ọba kan kalẹ̀,

ẹni ìgbàanì jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀.

Aṣọ rẹ̀ funfun ̀gbọ̀n òwú;

irun orí rẹ̀ funfun òwú,

ìtẹ́ ọba rẹ̀ ọwọ́ iná.

Àwọn kẹ̀kẹ́ rẹ ń i iná.

Odò iná ń sàn,

ó ń jáde iwájú rẹ̀ .

Àwọn ẹgbẹ̀rún lọ́ẹgbẹ̀rún ń ṣe ìránṣẹ́ fún un;

̀ẹgbẹẹgbàárùn-ún nígbà ẹgbàárùn-ún dúró níwájú rẹ̀.

Àwọn onídàájọ́ jókòó,

a ṣí ìwé wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀.

̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ó sùn nínú erùpẹ̀ ilẹ̀ ni yóò : àwọn mìíràn ìyè àìnípẹ̀kun, àwọn tókù ìtìjú àti ̀gàn àìnípẹ̀kun. Àwọn ó jẹ́ ọlọ́gbọ́n yóò máa tàn ìmọ́lẹ̀ ̀run, àti àwọn ó ń tọ́nisọ́òdodo, yóò máa tàn ìràwọ̀ láé àti láéláé.

Preparação para o juízo

Deus estabeleceu um dia para julgar o mundo com justiça. Arrependei-vos, porque o juízo se aproxima e cada palavra será pesada.

Níwọ́n ó ti ọjọ́ kan, nínú èyí yóò ṣe ìdájọ́ ayé lódodo nípasẹ̀ ọkùnrin náà ó ti yàn, nígbà ó ti fi ohun ìdánilójú fún gbogbo ènìyàn, ti ó dìde kúrò nínú òkú."

Ṣùgbọ́n, mo sọ èyí fún yín, ̀yin yóò jíyìn gbogbo ìsọkúsọ yín ọjọ́ ìdájọ́. Nítorí nípa ̀rọ̀ ẹnu yín ni a fi yin láre, nípa ̀rọ̀ ẹnu yín ni a ó fi yin lẹ́bi."

Àwọn àgùntàn àti ewúrẹ́

"Ṣùgbọ́n nígbà ti Ọmọ Ènìyàn yóò nínú ògo rẹ̀ pẹ̀gbogbo àwọn angẹli rẹ̀ nígbà náà ni yóò jókòó lórí ìtẹ́ ògo ̀run. Gbogbo orílẹ̀-èdè ni a ó kójọ níwájú rẹ̀, òun yóò ya àwọn ènìyàn ayé ̀tọ̀ gẹ́gẹ́ olùṣọ́-àgùntàn ṣe é ya àgùntàn kúrò lára àwọn ewúrẹ́. Òun yóò fi àgùntàn ọwọ́ ̀tún àti ewúrẹ́ ọwọ́ òsì.

Àwọn àgùntàn àti ewúrẹ́

"Ṣùgbọ́n nígbà ti Ọmọ Ènìyàn yóò nínú ògo rẹ̀ pẹ̀gbogbo àwọn angẹli rẹ̀ nígbà náà ni yóò jókòó lórí ìtẹ́ ògo ̀run. Gbogbo orílẹ̀-èdè ni a ó kójọ níwájú rẹ̀, òun yóò ya àwọn ènìyàn ayé ̀tọ̀ gẹ́gẹ́ olùṣọ́-àgùntàn ṣe é ya àgùntàn kúrò lára àwọn ewúrẹ́. Òun yóò fi àgùntàn ọwọ́ ̀tún àti ewúrẹ́ ọwọ́ òsì.

"Nígbà náà ni ọba yóò fún àwọn ó lọ́wọ́ ̀tún , , ̀yin Baba mi ti bùkún fún, jogún ìjọba a ti pèsè fún yín láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé. Nítorí ebi pa mi, ̀yin fún mi oúnjẹ, òǹgbẹ gbẹ , ̀yin fún mi omi. Mo jẹ́ àlejò, ̀yin sínú ilé yín. Mo ìhòhò, ̀yin daṣọ . Nígbà mo ṣe àìsàn ṣe ìtójú mi, àti ìgbà mo ọgbà ̀wọ̀n ̀yin bẹ̀ .

"Nígbà náà ni àwọn olódodo yóò fèsì , Olúwa, nígbà wo ni àwa ebi ń pa ́, a fún oúnjẹ? Tàbí òǹgbẹ ń gbẹ ́ a fún ohun mímu? Tàbí o jẹ́ àlejò a gbà ó sínú ilé wa? Tàbí o ìhòhò, a daṣọ ́? Nígbà wo ni a tilẹ̀ i o ṣe àìsàn, tàbí o ọgbà ̀wọ̀n, a bẹ̀ ́ ?

"Ọba náà yóò dáhùn yóò fún wọn , Lóòótọ́ ni mo fún yín níwọ̀n ìgbà ̀yin ṣe nǹkan wọ̀nyí fún àwọn arákùnrin mi yìí o kéré lọ, ̀ ń ṣe wọn fún mi ni.

"Nígbà náà ni yóò sọ fún àwọn ọwọ́ òsì , kúrò lọ́dọ̀ mi, ̀yin ẹni ègún, sínú iná àìnípẹ̀kun a ti tọ́fún èṣù àti àwọn angẹli rẹ̀. Nítorí ebi pa mi, ̀yin tilẹ̀ bọ́ mi, òrùngbẹ gbẹ mi, tilẹ̀ fún mi omi láti mu. Mo jẹ́ àlejò, ̀yin tilẹ̀ gbà mi sílé. Mo ìhòhò, ̀yin fi aṣọ mi. Mo ṣàìsàn, mo lọ́gbà ̀wọ̀n, ̀yin bẹ̀ .

"Nígbà náà àwọn pẹ̀yóò dáhùn , Olúwa, nígbà wo ni àwa , ebi ń pa ́ tàbí òǹgbẹ ń gbẹ ́, tàbí o ṣàìsàn, tàbí o lọ́gbà ̀wọ̀n, a ràn ́ lọ́wọ́?’

"Nígbà náà àwọn yóò dáhùn , Lóòótọ́ ni mo fún , nígbà ̀yin ti kọ̀ láti ran ̀kan nínú àwọn ó kéré lọ́wọ́ nínú arákùnrin mi, ̀yin kọ̀ láti ṣe ìrànlọ́wọ́ fún mi ni.

"Nígbà náà wọn yóò kọjá lọ sínú ìyà àìnípẹ̀kun, ṣùgbọ́n àwọn olódodo yóò lọ ìyè àìnípẹ̀kun."

Nítorí Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ olúkúlùkù iṣẹ́

àti ohun ìkọ̀kọ̀,

à ṣe rere à ṣe búburú.

Mo nínú ọkàn mi,

"Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́

olódodo àti ènìyàn búburú,

nítorí àsìkò yóò fún gbogbo iṣẹ́,

àti àsìkò ṣe ìdájọ́ gbogbo ìṣe."

"Nítorí náà, ilé Israẹli, èmi yóò da yín lẹ́jọ́, gẹ́gẹ́ ̀ẹnìkọ̀̀kan yín ṣe ni Olúwa Olódùmarè . yípadà! si kúrò nínú gbogbo ̀ṣẹ̀ yín, bẹ́̀ ni ìrékọjá yóò jẹ́ ̀ìṣubú yín. kọ̀ gbogbo ̀ṣẹ̀ ti ti sílẹ̀, gba ọkàn àti ̀tuntun. Nítorí fi máa , ilé Israẹli? Nítorí inú mi dùn ikú ẹnikẹ́ni ni Olúwa Olódùmarè . Nítorí náà, yípadà !

Segurança em Cristo

Quem crê no Filho tem a vida eterna e não entra em juízo. O amor de Deus é nosso refúgio diante do juízo vindouro.

"Nítorí Ọlọ́run fẹ́ aráyé bẹ́̀ gẹ́́, ó fi ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo fún ni, ẹnikẹ́ni ó gbà á gbọ́, á ṣègbé, ṣùgbọ́n ó ìyè àìnípẹ̀kun.

"Nítorí Ọlọ́run fẹ́ aráyé bẹ́̀ gẹ́́, ó fi ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo fún ni, ẹnikẹ́ni ó gbà á gbọ́, á ṣègbé, ṣùgbọ́n ó ìyè àìnípẹ̀kun. Nítorí Ọlọ́run rán ọmọ rẹ̀ ayé láti aráyé lẹ́jọ́; ṣùgbọ́n a le ti ipasẹ̀ rẹ̀ gba aráyé . Ẹni ó gbà á gbọ́, a a lẹ́jọ́; ṣùgbọ́n a ti ẹni gbà á gbọ́ lẹ́jọ́ , nítorí gba orúkọ ọmọ kan ṣoṣo ti Ọlọ́run gbọ́. Èyí ni ìdájọ́ náà , ìmọ́lẹ̀ ayé, àwọn ènìyàn fẹ́ òkùnkùn ju ìmọ́lẹ̀ lọ, nítorí iṣẹ́ wọn burú.

Ṣùgbọ́n òtítọ́ ni èmi ń sọ fún yín; àǹfààní ni yóò jẹ́ fún yín èmi lọ, nítorí èmi lọ, Olùtùnú yóò tọ̀ yín ; ṣùgbọ́n mo lọ, èmi ó rán an yín. Nígbà òun , yóò fi òye aráyé ti ̀ṣẹ̀, àti ti òdodo, àti ti ìdájọ́, ti ̀ṣẹ̀, nítorí wọn gbà gbọ́; ti òdodo, nítorí èmi ń lọ sọ́dọ̀ Baba, ̀yin mọ̀ . ti ìdájọ́, nítorí a ti ṣe ìdájọ́ ọmọ-aládé ayé yìí.

Báyìí ni àwa mọ̀, a gba ìfẹ́ Ọlọ́run wa gbọ́.

Ìfẹ́ ni Ọlọ́run; ẹni ó ń gbé inú ìfẹ́, ó ń gbé inú Ọlọ́run, àti Ọlọ́run nínú rẹ̀. Nínú èyí ni a ìfẹ́ ó nínú wa , àwa á ni ìgboyà ọjọ́ ìdájọ́: nítorí òun , bẹ́̀ ni àwa ni ayé yìí. Ìbẹ̀nínú ìfẹ́; ṣùgbọ́n ìfẹ́ ó ń ìbẹ̀jáde; nítorí ìbẹ̀ni ìyà nínú. Ẹni ó bẹ̀nínú ìfẹ́.

Nítorí gbogbo wa ni ó gbọdọ̀ fi ara hàn níwájú ìtẹ́ ìdájọ́ Kristi; olúkúlùkù gbà èyí ó ṣe gẹ́gẹ́ èyí ó tọ́ i nígbà ó nínú ara ìbá à ṣe rere tàbí búburú.

Èyí yóò farahàn ọjọ́ náà nígbà Ọlọ́run yóò tipasẹ̀ Jesu Kristi ṣe ìdájọ́ àwọn àṣírí ènìyàn gẹ́gẹ́ ìyìnrere mi.

Níwọ́n a ti fi lélẹ̀ fún gbogbo ènìyàn láti lẹ́̀kan ṣoṣo, ṣùgbọ́n lẹ́yìn èyí ìdájọ́, bẹ́̀ ni Kristi pẹ̀lẹ́yìn a ti fi ẹbọ lẹ́̀kan ṣoṣo láti ru ̀ṣẹ̀ ̀pọ̀lọpọ̀, yóò farahàn ìgbà kejì láìsí ̀ṣẹ̀ fún àwọn n wo ̀rẹ̀ fún ìgbàlà.

Nítorí,

"Ni ìwọ̀n ìgbà díẹ̀ i,

ẹni náà ti ń bọ̀ yóò ,

yóò jáfara.

Ṣùgbọ́n,

"Olódodo ni yóò nípa ìgbàgbọ́.

Ṣùgbọ́n o ba fàsẹ́yìn,

ọkàn mi inú dídùn i."

Ṣùgbọ́n àwa nínú àwọn ń fàsẹ́yìn sínú ègbé; ṣe nínú àwọn o gbàgbọ́ ìgbàlà ọkàn.

Nítorí náà, kíyèsára yín ṣe sùn àwọn ẹlòmíràn. máa ṣọ́máa pa ara yín mọ́. Nítorí àwọn wọ́n ń sùn, a máa sùn òru, àwọn ẹni ń mu àmupara, a máa un òru. Ṣùgbọ́n àwa jẹ́ ti ìmọ́lẹ̀, jẹ́ a pa ara wa mọ́, gbígbé ìgbàgbọ́ wọ̀ àti ìfẹ́ ìgbàyà ni òru àti ìrètí ìgbàlà àṣíborí. Nítorí , Ọlọ́run yàn wa láti da ìbínú rẹ̀ gbígbóná orí wa, ṣùgbọ́n ó yàn láti gbà nípasẹ̀ Olúwa wa, Jesu Kristi.

Wọn yóò kọrin níwájú Olúwa,

nítorí ó ń bọ̀ , ó ń bọ̀ ṣe ìdájọ́ ayé.

Yóò fi òdodo ṣe ìdájọ́ ayé

àti ti àwọn ènìyàn ni yóò fi òtítọ́ rẹ̀ ṣe.

Seja o primeiro

Este artigo te tocou? Faça uma oração!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.