Publicidade

Eclesiastes 12

1 Rántí Ẹlẹ́dàá rẹ

ọjọ́ èwe rẹ,

nígbà ọjọ́ ibi ì

àti ọdún ì súnmọ́ etílé, nígbà ìwọ yóò ,

"Èmi ìdùnnú nínú wọn,"

2 oòrùn àti ìmọ́lẹ̀

àti òṣùpá àti àwọn ìràwọ̀ ṣókùnkùn,

àti àwọsánmọ̀ padà lẹ́yìn òjò;

3 nígbà olùṣọ́ ilé yóò wárìrì

àwọn ọkùnrin alágbára yóò tẹríba,

nígbà àwọn ó ń lọ dákẹ́ nítorí wọn pọ̀,

àwọn ń wo òde láti ojú fèrèsé yóò ṣókùnkùn;

4 nígbà ìlẹ̀kùn ìgboro yóò

ariwo ọlọ yóò dákẹ́;

nígbà àwọn ènìyàn yóò dìde ariwo àwọn ẹyẹ

ṣùgbọ́n gbogbo orin wọn yóò máa lọ ilẹ̀.

5 Nígbà ènìyàn yóò bẹ̀ibi gíga

àti ti ìfarapa ìgboro;

nígbà igi almondi yóò tanná

àti ẹlẹ́ǹgà yóò wọ́ ara rẹ̀ lọ

ìfẹ́ ru sókè mọ́

nígbà náà ni ènìyàn yóò lọ ilé rẹ́ ayérayé

àwọn aṣọ̀fọ̀ yóò máa rìn kiri ìgboro.

6 Rántí rẹ̀ okùn fàdákà ,

tàbí ọpọ́n wúrà fọ́;

iṣà fọ́ níbi ìsun,

tàbí àyíká kẹ̀kẹ́ ó kán níbi kànga.

7 erùpẹ̀ yóò padà ilẹ̀ ibi ó ti ,

̀yóò padà sọ́dọ̀ Ọlọ́run ó fi í fún ni.

8 "Asán! Asán!" ni Oniwaasu .

"Gbogbo rẹ̀ asán ni!"

Òpin gbogbo ọrọ̀

9 í ṣe Oniwaasu jẹ́ ọlọ́gbọ́n nìkan, ṣùgbọ́n ó tún kọ́ àwọn ènìyàn ìmọ̀. Ó ó dáradára ó ṣe àwárí, ó gbé ̀pọ̀lọpọ̀ òwe kalẹ̀ lẹ́sẹẹsẹ. 10 Oniwaasu wádìí láti àwọn ̀rọ̀ ó tọ̀, ohun ó kọ dúró ṣinṣin ó jẹ́ òtítọ́.

11 ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n dàbí ̀gún, àkójọpọ̀ ̀rọ̀ wọn dàbí ìṣó a kàn pọ̀ dáradára, olùṣọ́-àgùntàn kan fi fún ni. 12 Àti síwájú láti inú èyí, ọmọ mi, gba ìmọ̀ràn.

Nínú ìwé púpọ̀, òpin , ìwé kíkà púpọ̀ a máa ara ṣàárẹ̀.

13 Nísinsin yìí,

òpin gbogbo ̀rọ̀ a gbọ́ ni ,

bẹ̀Ọlọ́run, o pa òfin rẹ̀ mọ́,

nítorí èyí ni ojúṣe gbogbo ènìyàn.

14 Nítorí Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ olúkúlùkù iṣẹ́

àti ohun ìkọ̀kọ̀,

à ṣe rere à ṣe búburú.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-