Publicidade

Frutos do Espírito

Por Bíblia Online

Os frutos do Espírito são evidências visíveis da presença de Deus na vida do crente. Amor, alegria, paz, paciência — são marcas que diferenciam os filhos de Deus no mundo.

O fruto do Espírito

O fruto do Espírito é amor, alegria, paz, paciência, amabilidade, bondade, fidelidade, mansidão e domínio próprio. Contra estas coisas não há lei.

Ṣùgbọ́n èso ti ̀ni ìfẹ́, ayọ̀, àlàáfíà, ìpamọ́ra, ìwà pẹ̀lẹ́, ìṣoore, ìgbàgbọ́, ìwà tútù, àti ìkóra-ẹni níjanu, òfin kan lòdì irú wọ̀nyí,

Nítorí ̀yin jẹ́ òkùnkùn lẹ́̀kan ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ̀yin ìmọ́lẹ̀, nípa Olúwa: máa rín gẹ́gẹ́ àwọn ọmọ ìmọ́lẹ̀ (nítorí èso ̀ni ìṣoore, àti òdodo àti òtítọ́). máa wádìí ohun í ṣe ìtẹ́wọ́gbà fún Olúwa.

Ṣùgbọ́n ọgbọ́n ó ti òkè jẹ́ mímọ́ àkọ́kọ́, ti àlàáfíà, àti ti ìrẹ̀lẹ̀, í í ṣòro láti bẹ̀, ó kún fún àánú àti fún èso rere, í ṣe ojúsàájú, a máa sọ òtítọ́. Àwọn ó ń ṣiṣẹ́ àlàáfíà a máa gbin èso àlàáfíà àlàáfíà.

Bẹ́̀ ni ̀yin ará mi, ̀yin pẹ̀ti di òkú òfin nípa ara Kristi, ̀yin ó ẹlòmíràn, àní ẹni náà a dìde kúrò nínú òkú, àwa ó so èso fún Ọlọ́run. Nítorí ìgbà a wa nípa ti ara, ìfẹ́kúfẹ̀́ ̀ṣẹ̀ nípa ti òfin, ma ń ṣiṣẹ́ nínú wa, a ń so èso ó yẹ fún ikú. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, nípa kíkú ohun so pọ̀ tẹ́lẹ̀ , a ti wa sílẹ̀ kúrò nínú òfin, a sin ín ìlànà tuntun ti ̀, í ṣe ìlànà àtijọ́ ìwé òfin gùnlé.

Àti , kín ni ìyọrísí rẹ̀? Dájúdájú àbájáde rẹ̀ dára. Níwọ́n ìgbà ojú ń ́ nísinsin yìí láti ronú nípa àwọn wọ̀n-ọn-nì o ti máa ń ṣe nítorí gbogbo wọn yọrí ìparun ayérayé. Ṣùgbọ́n báyìí, ti bọ́ kúrò lọ́wọ́ agbára ̀ṣẹ̀, ti di ẹrú Ọlọ́run àwọn ìbùkún rẹ̀ yin ni ìwà mímọ́ àti ìyè nípẹ̀kun.

Permanecer em Cristo

Quem permanece em Cristo dá muito fruto. Toda árvore boa produz bons frutos — e é pelo fruto que se conhece a árvore.

máa gbé inú mi, èmi ó máa gbé inú yín. Gẹ́gẹ́ ̀ka ti so èso fún ara rẹ̀ ṣe ó ba ń gbé inú àjàrà, bẹ́̀ ni ̀yin, ṣe ń gbé inú mi.

"Èmi ni àjàrà, ̀yin ni ̀ka. Ẹni ó ń gbé inú mi, àti èmi nínú rẹ̀, òun ni yóò so èso lọ́pọ̀lọ́pọ̀, nítorí yíya ara yín kúrò lọ́dọ̀ mi, ṣe ohun kan.

Nínú èyí a yìn Baba mi lógo , ̀yin ó máa so èso púpọ̀; ̀yin ó jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn mi.

Igi àti èso rẹ̀

"Nítorí igi rere í so èso búburú; bẹ́̀ ni igi búburú í so èso rere. Olúkúlùkù igi ni a ń fi èso rẹ̀ mọ̀ ọn; nítorí lórí ̀gún òṣùṣú, ènìyàn í èso ̀pọ̀tọ́ bẹ́̀ ni lórí ̀gún ̀gàn a í èso àjàrà. Ènìyàn rere láti inú yàrá ìṣúra rere ọkàn rẹ̀ ohun rere jáde ; àti ènìyàn búburú láti inú ìṣúra búburú ọkàn rẹ̀ í ohun búburú jáde : nítorí láti inú ̀kúnrẹ́rẹ́ ọkàn ẹnu ti máa sọ jáde.

so èso ó yẹ fún ìrònúpìwàdà.

Semear e colher

Quem semeia na justiça colherá fruto de vida. Os frutos do Espírito são a colheita de uma vida plantada no Senhor.

gbin òdòdó fún ara yín,

èso ìfẹ́ àìlópin.

tu ilẹ̀ yín a ro,

nítorí ó ti àsìkò láti Olúwa,

títí yóò fi ,

yóò rọ òjò òdodo yín lórí.

sọ fún olódodo yóò dára fún wọn,

nítorí àjẹgbádùn ni wọn yóò jẹ èso iṣẹ́ wọn.

í ṣe àwọn nìkan, ṣùgbọ́n àwa tìkára wa pẹ̀, a ni àkóso ̀, àní àwa tìkára wa ń kérora nínú ara wa, àwa ń dúró de ìsọdọmọ àní ìdáǹdè ara wa.

Èso mi dára ju wúrà dáradára lọ;

ohun ń ju àṣàyàn fàdákà lọ.

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-