Publicidade

Oséias 10

1 Israẹli jẹ́ igi àjàrà gbilẹ̀

ó ń so èso fún ara rẹ̀.

èso rẹ̀ ṣe ń pọ̀

bẹ́̀ ni ó ń kọ́ pẹpẹ i

ilẹ̀ rẹ̀ ṣe ń ṣe rere

o bu ọlá fún òkúta ìyàsọ́tọ̀ ère rẹ̀.

2 Ọkàn wọn kún fún ìtànjẹ

báyìí wọ́n gbọdọ̀ ru ̀bi wọn.

Olúwa yóò pẹpẹ wọn palẹ̀

yóò pa gbogbo òkúta ìyàsọ́tọ̀ wọn run.

3 Nígbà náà ni wọn yóò , "A ọba

nítorí a bọ̀wọ̀ fún Olúwa

ṣùgbọ́n a tilẹ̀ ọba,

ni yóò ṣe fún wa?"

4 Wọ́n ṣe ìlérí púpọ̀,

wọ́n ṣe ìbúra èké,

wọ́n da májẹ̀;

báyìí ni ìdájọ́ sókè igi ìwọ̀ ni aporo oko,

bi i koríko májèlé láàrín oko a ro.

5 Àwọn ènìyàn ń gbé Samaria bẹ̀

nítorí ère abo màlúù Beti-Afeni.

Àwọn ènìyàn rẹ̀ yóò ṣọ̀fọ̀ le e lórí

bẹ́̀ ni àwọn àlùfáà abọ̀rìṣà rẹ̀.

Gbogbo àwọn láyọ̀ dídán rẹ̀,

nítorí a ti lọ ìgbèkùn.

6 A ó gbé lọ Asiria

gẹ́gẹ́ ̀bùn fún ọba ńlá

a ó dójútì Efraimu;

ojú yóò ti Israẹli nítorí ìgbìmọ̀ rẹ̀.

7 igi léfòó lórí omi ni

Samaria àti àwọn ọba rẹ yóò sàn lọ.

8 Àwọn ibi gíga ń hùwà búburú ni a o parun,

èyí ni ̀ṣẹ̀ Israẹli.

̀gún ̀gàn àti ̀gún òṣùṣú yóò jáde,

yóò bo àwọn pẹpẹ wọn.

Wọn yóò sọ fún àwọn òkè gíga , "mọ́lẹ̀!"

àti fún àwọn òkè kéékèèké , "Ṣubú !"

9 "Láti ìgbà Gibeah, ni ó ti ṣẹ̀, ìwọ Israẹli,

ìwọ tún níbẹ̀.

Ǹjẹ́ ogun ̀yin aṣebi

ni Gibeah ?

10 Nígbà tẹ́ mi lọ́rùn, èmi yóò fi ìyà jẹ wọ́n;

Orílẹ̀-èdè yóò ra wọn jọ, wọ́n ó dojúkọ wọn,

láti fi wọn sínú ìdè nítorí ìlọ́po ̀ṣẹ̀ wọn.

11 Efraimu jẹ́ ọmọ abo màlúù a kọ́,

to si fẹ́ràn láti máa pa ọkà;

lórí ọrun rẹ̀ lẹ́ni

èmi ó ẹrù wúwo .

Èmi yóò a gun Efraimu ẹṣin

Juda yóò ilẹ̀,

Jakọbu yóò fọ́ ògúlùtu rẹ̀.

12 gbin òdòdó fún ara yín,

èso ìfẹ́ àìlópin.

tu ilẹ̀ yín a ro,

nítorí ó ti àsìkò láti Olúwa,

títí yóò fi ,

yóò rọ òjò òdodo yín lórí.

13 Ṣùgbọ́n gbin búburú si ka ibi,

ti jẹ èso èké

nítorí gbẹ́kẹ̀agbára yín

àti àwọn ̀pọ̀ jagunjagun yín,

14 ariwo ogun yóò bo àwọn ènìyàn yín

gbogbo odi agbára yín ba le parun.

Gẹ́gẹ́ Ṣalmani ṣe pa Beti-Arbeli run lọ́jọ́ ogun,

nígbà a gbé àwọn ìyá ṣánlẹ̀ pẹ̀àwọn ọmọ wọn.

15 Báyìí ni a o ṣe , ìwọ Beteli,

nítorí ìwà búburú yín ti pọ̀.

àfẹ̀mọ́júmọ́ ọjọ́ náà,

a o pa ọba Israẹli run pátápátá.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-