Publicidade

Isaías 3

Ìdájọ́ lórí i Jerusalẹmu àti Juda

1 Kíyèsi i, Olúwa,

Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

fẹ́ ìpèsè àti ìrànlọ́wọ́ kúrò Jerusalẹmu àti Juda

gbogbo ìpèsè oúnjẹ àti ìpèsè omi.

2 Àwọn akíkanjú àti jagunjagun,

adájọ́ àti wòlíì,

aláfọ̀ṣẹ àti alàgbà,

3 balógun àádọ́ta àti àwọn ènìyàn, onípò gíga;

olùdámọ̀ràn, oníṣọ̀ó dáńtọ́ àti ògbójú oníṣègùn.

4 "Èmi ó sọ àwọn ̀dọ́mọkùnrin di aláṣẹ wọn,

̀dọ́mọdé lásán làsàn ni yóò

máa jẹ ọba lórí i wọn."

5 Àwọn ènìyàn yóò máa pọ́n ọmọnìkejì,

wọn lójú ẹnìkan ẹnìkejì rẹ̀, aládùúgbò aládùúgbò rẹ̀.

Àwọn ̀dọ́ yóò gbógun ti àwọn àgbàgbà,

àwọn mẹ̀kúnnù yóò dìde ọlọ́.

6 Ọkùnrin kan yóò di ̀kan nínú àwọn

arákùnrin rẹ̀ ,

nínú ilé baba rẹ̀, yóò ,

"Ìwọ́ aṣọ, ìwọ máa ṣe olórí wa,

mójútó àwọn ahoro wọ̀nyí!"

7 Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà ni yóò figbe bọnu ,

"Èmi àtúnṣe kan.

Èmi oúnjẹ, bẹ́̀ ni n ó aṣọ nílé,

fi ṣe olórí àwọn ènìyàn náà."

8 Jerusalẹmu ń ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n

Juda ń ṣubú lọ,

̀rọ̀ àti ìṣe wọn lòdì Olúwa,

láti ojú ògo rẹ̀ bínú.

9 Ìwò ojú wọn ń jẹ́rìí lòdì wọn,

wọ́n ń polongo ̀ṣẹ̀ wọn i Sodomu;

wọn ò fi pamọ́!

Ègbé ni fún wọn!

Wọ́n ti ìparun sórí ara wọn.

10 sọ fún olódodo yóò dára fún wọn,

nítorí àjẹgbádùn ni wọn yóò jẹ èso iṣẹ́ wọn.

11 Ègbé ni fún ènìyàn búburú! Ìparun lórí i wọn,

a ó san èrè iṣẹ́ ọwọ́ wọn ti ṣe fún wọn.

12 Àwọn ̀dọ́mọdé ni o ń pọ́n àwọn ènìyàn mi lójú

àwọn obìnrin ń jẹ ọba wọn lórí.

Háà! Ènìyàn mi àwọn afinimọ̀yín ti ṣì yín lọ́,

wọn yín kúrò ipa ̀yín.

13 Olúwa bọ ipò rẹ̀ ìtẹ́ ìdájọ́

Ó dìde láti àwọn ènìyàn lẹ́jọ́.

14 Olúwa dojú ẹjọ́ kọ

àwọn àgbàgbà àti àwọn olórí àwọn ènìyàn rẹ̀.

"̀yin ni ti run ọgbà àjàrà mi,

ogún àwọn tálákà ń bẹ̀ nínú ilé yín.

15 Kín ni èrò yín láti máa run àwọn ènìyàn mi túútúú

fojú àwọn tálákà ni gbolẹ̀?"

ni Olúwa , Olúwa àwọn ọmọ-ogun.

16 Olúwa ,

"Àwọn obìnrin Sioni jẹ́ agbéraga,

wọn ń rìn lọ pẹ̀ọrùn ó tàntàn,

wọn ń fojú pe ọkùnrin,

wọn ń sọ̀wọ́n ti ń yan lọ

pẹ̀ohun ̀ṣọ́ ń wọnjanwọnjan lọ́rùn ẹsẹ̀ wọn.

17 Nítorí náà Olúwa yóò egbò sórí àwọn obìnrin Sioni,

Olúwa yóò wọn agbárí."

18 ọjọ́ náà, Olúwa yóò ̀ṣọ́ wọn gbà kúrò ti ọwọ́ àti gèlè àti ̀gbà ọrùn ó dàbí òṣùpá 19 gbogbo yẹtí, ̀gbà ọwọ́ àti ìbòjú, 20 gbogbo gèlè, ̀gbà ọrùn, ẹsẹ̀ àti àyà, àwọn ìgò tùràrí àti òògùn, 21 òrùka ọwọ́ àti ti imú, 22 àwọn àtàtà aṣọ, àwọ̀lékè, agbádá àti àpamọ́wọ́, 23 dígí wọn, aṣọ funfun nigínnigín ìbòrí àti ìbòjú.

24 Dípò òórùn dídùn, òórùn búburú ni yóò ,

okùn ni yóò dípò àmùrè,

orí pípá ni yóò dípò irun ti a ṣe ̀ṣọ́

aṣọ ̀fọ̀ ni yóò dípò aṣọ ̀yẹ ìjóná dípò ẹwà.

25 Àwọn ọkùnrin rẹ yóò ti ipa idà ṣubú,

àti àwọn jagunjagun rẹ̀ lójú ogun.

26 Àwọn bodè Sioni yóò sọkún kíkorò, wọn ó ṣọ̀fọ̀,

nítorí ó dahoro, yóò jókòó orí ilẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-