Pular para o conteúdo
Publicidade

Planejamento

Por Bíblia Online

O planejamento é sábio, mas deve sempre se submeter à vontade de Deus. A Bíblia ensina que devemos planejar com prudência, mas confiar que Deus dirige nossos passos.

Planejar com sabedoria

Contar nossos dias nos ensina a ter coração sábio. O planejamento prudente é elogiado na Escritura como expressão de bom senso.

Kọ́ wa a ti ń kaye ọjọ́ wa dáradára,

àwa ba à fi ọkàn wa sípa ọgbọ́n.

"Nítorí ta ni nínú yín ń pète láti kọ́ ilé ìṣọ́, yóò kọ́kọ́ jókòó ó ṣírò iye owó rẹ̀, òun yóò fi parí rẹ̀.

Ìgbèrò a máa dasán níbi ìmọ̀ràn;

ṣùgbọ́n a máa yege níbi ̀pọ̀lọpọ̀ olùbádámọ̀ràn .

Fi ohun gbogbo o ṣe Olúwa lọ́wọ́,

èrò rẹ yóò ṣe é ṣe.

ṣe ṣe làálàá láti lọ́rọ̀:

ṣíwọ́ kúrò nínú ọgbọ́n ara rẹ.

Deus dirige os passos

O coração do homem planeja, mas a resposta certa vem do Senhor. Seus caminhos são mais altos que os nossos, e seus planos prevalecem.

Ènìyàn a máa pète ̀ara rẹ̀ lọ́kàn an rẹ̀

ṣùgbọ́n Olúwa í pinnu ìgbésẹ̀ rẹ̀.

̀pọ̀lọpọ̀ ni ète inú ọkàn ènìyàn,

ṣùgbọ́n ìfẹ́ Olúwa ó máa ń borí.

"Nítorí èrò mi í ṣe èrò yín,

tàbí ̀yín a ha máa ṣe ̀mi,"

ni Olúwa .

"Gẹ́gẹ́ ̀run ti ga ju ayé lọ,

bẹ́̀ ni ̀mi ga ju ̀yín lọ

àti èrò mi ju èrò yín lọ.

Gbogbo èyí pẹ̀ti ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun ,

oníyanu ìmọ̀ràn àti ológo ọgbọ́n.

Confiança no plano de Deus

Os planos do Senhor são de paz e esperança. Ele revela seus segredos aos seus servos e guia com fidelidade cada caminho confiado a Ele.

Nítorí mo mọ èrò mo yín," ni Olúwa , "àní èrò àlàáfíà, í ṣe fún ibi, èrò láti fún un yín ìgbà ìkẹyìn àti ìrètí ọjọ́ iwájú.

Nítòótọ́ Olúwa Olódùmarè ṣe ohun kan

láìfi èrò rẹ̀ hàn

fun àwọn wòlíì ìránṣẹ́ rẹ̀.

ó fi fún gẹ́gẹ́ bi ti èrò ọkàn rẹ

ó gbogbo ìmọ̀ rẹ ṣẹ.

mi gbọ́ ìṣeun ìfẹ́ rẹ òwúrọ̀:

nítorí ìwọ ni mo gbẹ́kẹ̀.

Fi ̀èmi i rìn hàn ,

nítorí èmi gbé ọkàn mi sókè .

Àkókò àti ìgbà fún ohun gbogbo

Àsìkò fún ohun gbogbo,

àti ìgbà fún gbogbo nǹkan abẹ́ ̀run.

Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ti fi í hàn fún wa nípasẹ̀ ̀rẹ̀.

̀á máa wádìí ohun gbogbo, kódà àwọn àṣírí Ọlọ́run jinlẹ̀ jùlọ.

ṣe ṣe ìlara ènìyàn jàgídíjàgan

tàbí o yàn láti rìn ̀rẹ̀.

Nítorí Olúwa kórìíra ènìyàn aláyídáyidà

ṣùgbọ́n a máa fọkàn tán ẹni dídúró ṣinṣin.

Seja o primeiro