Publicidade

Isaías 28

Ègbé ni fún Efraimu

1 Ègbé ni fún adé ìgbéraga,

fún àwọn ̀mùtí Efraimu,

àti fún ìtànná rírọ, ẹwà ògo rẹ̀,

ó orí àfonífojì ẹlẹ́lójú

àti ìlú náà

ìgbéraga àwọn ọtí wáìnì ń pa a rẹ̀ sílẹ̀.

2 Kíyèsi i, Olúwa ẹnìkan ó le, ó lágbára,

gẹ́gẹ́ ̀wọ́ yìnyín àti ìjì apanirun,

gẹ́gẹ́ àrọ̀òjò àti òjò ó ìkún omi ,

òun yóò fi tipátipá sọ ́ sílẹ̀.

3 Adé ìgbéraga àwọn ̀mùtí Efraimu,

ni a ó fi ẹsẹ̀ tẹ̀ mọ́lẹ̀.

4 Òdòdó ó ń rọ náà í ṣe ẹwà ògo rẹ̀,

ó orí àfonífojì ẹlẹ́lójú,

yóò dàbí èso ̀pọ̀tọ́ ó pọ́n ṣáájú ìkórè

ẹnikẹ́ni ti i ó un ọwọ́ rẹ̀,

òun a ín.

5 ọjọ́ náà Olúwa àwọn ọmọ-ogun

yóò jẹ́ adé ó lógo,

àti adé ó lẹ́

fún àwọn ènìyàn rẹ̀ ó ṣẹ́.

6 Òun yóò jẹ́ ̀ìdájọ́ òdodo

fún ẹni ó jókòó ìtẹ́ ìdájọ́

àti orísun agbára

fún àwọn ẹni ó ń ogun padà ẹnu ibodè.

7 Àwọn wọ̀nyí pẹ̀ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n fún ọtí wáìnì

wọ́n pòòrì fún ọtí líle,

àwọn àlùfáà àti wòlíì ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n fún ọtí líle

wọ́n ta gíẹ́ gíẹ́ fún ọtí wáìnì

wọ́n ń lọ́ bìrì bìrì fún ọtí líle,

wọ́n ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nígbà wọ́n ń ríran,

wọ́n kọsẹ̀ nígbà wọ́n ń ìpinnu .

8 Gbogbo orí tábìlì ni ó kún fún èébì

ṣí ibìkan ̀gbin.

9 "Ta ni ẹni náà ó ń gbìyànjú àti kọ́?

Ta ni ó ń ṣàlàyé ìròyìn in rẹ̀ fún?

àwọn ọmọdé a lẹ́nu ọmú wọn,

àwọn a ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà lẹ́nu ọmú.

10 Nítorí í ṣe: báyìí ni orí,

ṣe, o si túnṣe, ṣe o si túnṣe,

àṣẹ n gorí àṣẹ, àṣẹ n gorí àṣẹ;

díẹ̀ níhìn-ín, díẹ̀ lọ́hùn."

11 Ó dára báyìí, pẹ̀ètè àjèjì àti ahọ́n àìmọ̀

Ọlọ́run yóò àwọn ènìyàn yìí sọ̀rọ̀

12 àwọn ó sọ fún ,

"Èyí ni ibi ìsinmi, jẹ́ àwọn aláàárẹ̀ sinmi";

àti , "Èyí ni ibi ìsinmi";

ṣùgbọ́n wọn tẹ́sílẹ̀.

13 Fún ìdí èyí, ̀rọ̀ Olúwa wọn yóò di ,

ṣe èyí, ṣe ìyẹn,

àṣẹ n gorí àṣẹ, àṣẹ n gorí àṣẹ;

díẹ̀ níhìn-ín, díẹ̀ lọ́hùn,

bẹ́̀ ni wọn yóò lọ wọn yóò tún ṣubú sẹ́yìn,

wọn yóò fi ara pa, wọn yóò bọ́ sínú okùn a ó gbá wọn .

14 Nítorí náà, gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa, ̀yin ẹlẹ́gàn,

ń jẹ ọba lórí àwọn ènìyàn wọ̀nyí Jerusalẹmu.

15 fọ́n , "Àwa ti ikú mulẹ̀,

pẹ̀ibojì ni àwa ti jọ ṣe àdéhùn.

Nígbà ìbáwí gbígbóná fẹ́ kọjá,

le kàn lára,

nítorí a ti fi irọ́ ṣe ààbò o wa

àti àìṣòótọ́ ibi ìpamọ́ wa."

16 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè :

"Kíyèsi i, èmi gbé òkúta kan lélẹ̀ Sioni, òkúta a dánwò,

òkúta igun ilé iyebíye fún ìpìlẹ̀ ó dájú;

ẹnikẹ́ni ó gbẹ́kẹ̀

yóò ìfòyà.

17 Èmi yóò fi ìdájọ́ ṣe okùn òsùwọ̀n

àti òdodo òjé òsùwọ̀n;

yìnyín yóò gbá ààbò yín dànù àti irọ́,

omi yóò kún bo gbogbo ibi

ń fi ara pamọ́ mọ́lẹ̀.

18 Májẹ̀yín ikú ni a ó fa igi ;

àdéhùn yín pẹ̀ibojì ni yóò dúró.

Nígbà ìbínú gbígbóná náà fẹ́ kọjá,

a ó ti ipa rẹ̀ yín bolẹ̀.

19 Nígbàkígbà ó ti ni

yóò máa gbé lọ,

ni àràárọ̀, ̀sán àti òru,

ni yóò máa fẹ́ kọjá lọ."

Ìmòye ̀rọ̀-ìmọ̀ yìí

yóò máa ìpayà ńlá .

20 Ibùsùn kúrú púpọ̀ fún ìnara lórí,

ìbora fẹ̀ láti ara yín .

21 Olúwa yóò dìde sókè gẹ́gẹ́ ó ti ṣe

òkè Perasimu

yóò ru ara rẹ̀ sókè gẹ́gẹ́ ó ti ṣe

àfonífojì Gibeoni

láti ṣe iṣẹ́ rẹ̀, abàmì iṣẹ́ rẹ̀,

yóò ṣe iṣẹ́ rẹ̀, àní àjèjì iṣẹ́ rẹ̀.

22 ìsinsin yìí dákẹ́ ẹlẹ́ṣíṣe,

bẹ́̀ kọ́ ìdè e yín yóò le i;

Olúwa, àní Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti sọ fún mi

nípa àṣẹ ìparun ti ó ti pa lórí gbogbo ilẹ̀ náà.

23 Tẹ́o gbọ́ ohùn mi,

fi ara balẹ̀ o gbọ́ ohun mo sọ.

24 Nígbà àgbẹ̀ kan tu ilẹ̀ láti gbìn

yóò ha máa tulẹ̀ títí bi?

Ǹjẹ́ yóò ha máa tu ilẹ̀

ó máa jọ̀ ́ títí lọ ?

25 Nígbà òun ti tẹ́ ojú ilẹ̀ rẹ̀ pẹrẹsẹ

òun ha ń fúnrúgbìn dílì

ó fúnrúgbìn kummini ?

ó gbin alikama lẹ́sẹẹsẹ,

barle a yàn,

àti spelti ipò rẹ̀?

26 Ọlọ́run rẹ̀ tọ́ ṣọ́

ó kọ́ lẹ́kọ̀́ ̀tọ́.

27 Nítorí a fi ohun èlò ìpakà dili,

bẹ́̀ ni a í kẹ̀kẹ́ ẹrù kiri lórí kummini;

ṣùgbọ́n ̀ni a fi ń pa dili jáde,

̀gọ ni a lu kummini.

28 A gbọdọ̀ lọ ìyẹ̀fun a ṣe àkàrà;

bẹ́̀ ni ẹnìkan í máa pa á lọ títí láé.

ó tilẹ̀ ẹsẹ̀ kẹ̀kẹ́ ìpakà a rẹ̀ lórí i rẹ̀,

àwọn ẹṣin rẹ̀ le lọ̀ ́.

29 Gbogbo èyí pẹ̀ti ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun ,

oníyanu ìmọ̀ràn àti ológo ọgbọ́n.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-