Publicidade

Poder de decisão

Por Bíblia Online

Deus nos deu o poder de escolher. A Bíblia mostra que nossas decisões têm consequências eternas e nos chama a escolher sabiamente — a vida, a fé e o caminho de Deus.

A responsabilidade de escolher

Escolhei hoje a quem servireis. Cada decisão molda nosso destino, e Deus nos convida a escolher o caminho da vida e da obediência.

Ṣùgbọ́n ̀yin fẹ́ láti sin Olúwa, nígbà náà yàn fún ara yín òní ẹni ̀yin yóò sìn bóyá òrìṣà àwọn baba ńlá yín sìn ìkọjá odò Eufurate, tàbí òrìṣà àwọn ará Amori, ilẹ̀ ẹni ̀yin ń gbé. Ṣùgbọ́n ti èmi àti ilé mi, Olúwa ni àwa yóò máa sìn."

Lẹ́yìn náà ni Joṣua , "̀yin ni ẹlẹ́rìí ara yín , ti yàn láti sin Olúwa."

Wọ́n dáhùn , "Bẹ́̀ ni, àwa ni ẹlẹ́rìí."

"Nítorí náà, ilé Israẹli, èmi yóò da yín lẹ́jọ́, gẹ́gẹ́ ̀ẹnìkọ̀̀kan yín ṣe ni Olúwa Olódùmarè . yípadà! si kúrò nínú gbogbo ̀ṣẹ̀ yín, bẹ́̀ ni ìrékọjá yóò jẹ́ ̀ìṣubú yín. kọ̀ gbogbo ̀ṣẹ̀ ti ti sílẹ̀, gba ọkàn àti ̀tuntun. Nítorí fi máa , ilé Israẹli? Nítorí inú mi dùn ikú ẹnikẹ́ni ni Olúwa Olódùmarè . Nítorí náà, yípadà !

Èmi mọ̀ iṣẹ́ rẹ, ìwọ gbóná bẹ́̀ ni ìwọ tútù: èmi ìbá fẹ́ ìwọ kúkú tutù, tàbí ìwọ kúkú gbóná. Ǹjẹ́ nítorí ìwọ lọ wọ́́rọ́, o si gbóná, bẹ́̀ ni o tutù, èmi yóò pọ̀ ́ jáde kúrò ni ẹnu mi.

Decisões e consequências

Deus retribuirá a cada um segundo as suas obras. As Escrituras nos alertam que a mornidão espiritual e a resistência ao Espírito têm consequências sérias.

Ọlọ́run yóò san án fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀. Àwọn ẹni ń fi sùúrù nínú rere ṣíṣe, ògo àti ọlá àti àìdíbàjẹ́ ni yóò fi ìyè àìnípẹ̀kun fún. Ṣùgbọ́n fún àwọn onímọ̀-tara-ẹni-nìkan, wọn gba òtítọ́ gbọ́, ṣùgbọ́n wọn ń tẹ̀̀búburú, wọn yóò ìrírí ìrunú àti ìbínú rẹ̀.

"̀yin ọlọ́rùn líle àti aláìkọlà àyà àti etí! àwọn baba yín gẹ́lẹ́ ni ̀yin . Nígbà gbogbo ni ̀yin máa ń dènà ̀Mímọ́!

Nítorí náà ṣe gbé ìgboyà yín sọnù, èyí ti o ni èrè ńlá.

Nítorí ̀yin le ṣe aláìní sùúrù, nítorí ìgbà ̀yin ti ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run tan ̀yin le gba ìlérí náà. Nítorí,

"Ni ìwọ̀n ìgbà díẹ̀ i,

ẹni náà ti ń bọ̀ yóò ,

yóò jáfara.

Ṣùgbọ́n,

"Olódodo ni yóò nípa ìgbàgbọ́.

Ṣùgbọ́n o ba fàsẹ́yìn,

ọkàn mi inú dídùn i."

Ṣùgbọ́n àwa nínú àwọn ń fàsẹ́yìn sínú ègbé; ṣe nínú àwọn o gbàgbọ́ ìgbàlà ọkàn.

Decisão e fé

Decida com fé, entregue seus planos ao Senhor e aja com determinação. Deus guia os passos de quem se achega a Ele de coração.

A ṣẹ́ kèké si ìṣẹ́po aṣọ,

ṣùgbọ́n gbogbo ìdájọ́ rẹ̀ láti ̀dọ̀ Olúwa.

̀pọ̀lọpọ̀ ni ète inú ọkàn ènìyàn,

ṣùgbọ́n ìfẹ́ Olúwa ó máa ń borí.

Fi ohun gbogbo o ṣe Olúwa lọ́wọ́,

èrò rẹ yóò ṣe é ṣe.

Nítorí Olúwa Olódùmarè ràn lọ́wọ́,

a yóò dójútì .

Nítorí náà ni mo ṣe gbé ojú mi òkúta akọ

èmi mọ , ojú .

ẹnikẹ́ni fẹ́ láti ṣe ìfẹ́ rẹ̀ yóò mọ̀ ti ̀kọ́ náà, ìbá ṣe ti Ọlọ́run, tàbí èmi sọ ti ara mi.

Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi, èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run wọn. Èmi ó fún wọn ọkàn kan àti ìṣe wọn ó máa bẹ̀mi fún rere wọn àti fún rere àwọn ọmọ wọn ó tẹ̀wọn.

Peteru fún wọn , "ronúpìwàdà, a bamitiisi olúkúlùkù yín orúkọ Jesu Kristi fún ìdáríjì ̀ṣẹ̀ yín. ̀yin yóò gba ̀bùn ̀Mímọ́.

Nítorí náà, tẹríba fún Ọlọ́run. kọ ojú ìjà èṣù, òun ó kúrò lọ́dọ̀ yín. súnmọ́ Ọlọ́run, òun ó súnmọ́ yín. wẹ ọwọ́ yín mọ́, ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀; ṣe ọkàn yín mímọ́, ̀yin oníyèméjì.

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-