Publicidade

Josué 24

Májẹ̀di ̀tun Ṣekemu

1 Nígbà náà ni Joṣua pe gbogbo àwọn ̀Israẹli jọ Ṣekemu. Ó pe àwọn àgbàgbà, àwọn olórí, onídàájọ́ àti àwọn ìjòyè Israẹli, wọ́n fi ara wọn hàn níwájú Ọlọ́run.

2 Joṣua sọ fun gbogbo ènìyàn , "Báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli, , Nígbà kan àwọn baba ńlá yín Tẹra baba Abrahamu àti Nahori ń gbé ìkọjá odò Eufurate, wọ́n sin àwọn òrìṣà. 3 Ṣùgbọ́n mo Abrahamu baba yín kúrò ìkọjá odò Eufurate, mo ṣe amọ̀rẹ̀ ni gbogbo Kenaani, mo fún àwọn ọmọ púpọ̀. Mo fún Isaaki, 4 àti fún Isaaki ni mo fún Jakọbu àti Esau, mo fún Esau ilẹ̀ orí òkè Seiri ìní, ṣùgbọ́n Jakọbu àti àwọn ọmọ rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ Ejibiti.

5 " Nígbà náà ni mo rán Mose àti Aaroni, mo yọ Ejibiti lẹ́nu ti nǹkan mo ṣe níbẹ̀, mo yín jáde. 6 Nígbà mo àwọn baba yín jáde kúrò Ejibiti, Òkun, àwọn ará Ejibiti lépa wọn pẹ̀kẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn ẹlẹ́ṣin títí ó fi Òkun Pupa. 7 Ṣùgbọ́n wọ́n pe Olúwa fún ìrànlọ́wọ́, ó fi òkùnkùn àárín yín àti àwọn ará Ejibiti, ó òkun orí wọn; ó wọ́n mọ́lẹ̀. fi ojú yín ohun mo ṣe àwọn ará Ejibiti. Lẹ́yìn náà gbé aginjù fún ọjọ́ pípẹ́.

8 " Èmi yín ilẹ̀ àwọn ará Amori ó ń gbé ìlà-oòrùn Jordani. Wọ́n yín , ṣùgbọ́n mo fi wọ́n yín lọ́wọ́. Èmí pa wọ́n run kúrò níwájú u yín, gba ilẹ̀ wọn. 9 Nígbà Balaki ọmọ Sippori, ọba Moabu, múra láti Israẹli , ó ránṣẹ́ Balaamu ọmọ Beori láti fi yín . 10 Ṣùgbọ́n èmi fetí Balaamu, bẹ́̀ ni ó súre fún un yín síwájú àti síwájú i, mo gbà yín kúrò ọwọ́ rẹ̀.

11 " Lẹ́yìn náà ni rékọjá Jordani, Jeriko. Àwọn ará ìlú Jeriko yín , gẹ́gẹ́ ará Amori, Peresi, Kenaani, Hiti, Girgaṣi, Hifi àti Jebusi. Ṣùgbọ́n mo fi wọ́n e yín lọ́wọ́. 12 Èmi rán oyin iwájú yín, ó wọn kúrò iwájú yín, àní ọba Amori méjì. ṣe èyí pẹ̀idà yín àti ọrun yín. 13 Bẹ́̀ ni mo fún un yín ilẹ̀ ̀yin ṣiṣẹ́ fún, àti àwọn ìlú ̀ yin kọ́; ń gbé inú wọn, ń jẹ nínú ọgbà àjàrà àti ọgbà olifi gbìn.

14 "Nísinsin yìí bẹ̀Olúwa, máa sìn ín òtítọ́ àti òdodo. òrìṣà àwọn baba ńlá yín sìn ìkọjá odò Eufurate àti Ejibiti kúrò, máa sin Olúwa. 15 Ṣùgbọ́n ̀yin fẹ́ láti sin Olúwa, nígbà náà yàn fún ara yín òní ẹni ̀yin yóò sìn bóyá òrìṣà àwọn baba ńlá yín sìn ìkọjá odò Eufurate, tàbí òrìṣà àwọn ará Amori, ilẹ̀ ẹni ̀yin ń gbé. Ṣùgbọ́n ti èmi àti ilé mi, Olúwa ni àwa yóò máa sìn."

16 Àwọn ènìyàn dáhùn , "a ri àwa yóò fi kọ Olúwa sílẹ̀ láti sin òrìṣà! 17 Nítorí Olúwa Ọlọ́run fúnra rẹ̀ ni ó gba àwọn baba ńlá wa kúrò Ejibiti, oko ẹrú. Òun ni Ọlọ́run ó ṣe iṣẹ́ ìyanu ńlá níwájú àwọn ọmọ Israẹli. Ó pa mọ́ nínú gbogbo ìrìnàjò wa àti àárín gbogbo orílẹ̀-èdè a kọjá. 18 Olúwa gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè jáde kúrò iwájú wa, pẹ̀àwọn Amori, ń gbé ilẹ̀ náà. Àwa náà yóò máa sin Olúwa, nítorí òun ni Ọlọ́run wa."

19 Joṣua fún àwọn ènìyàn náà, , "̀yin le sin Olúwa, nítorí Ọlọ́run mímọ́ ni òun; Ọlọ́run owú ni òun, yóò dárí ìrékọjá àti ̀ṣẹ̀ yín yín. 20 kọ Olúwa sin òrìṣà orílẹ̀-èdè mìíràn òun yóò padà yóò ibi a yín, yóò pa yín run, lẹ́yìn ìgbà ó ti ṣe rere fún un yín tan."

21 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn sọ fún Joṣua , "Bẹ́̀ kọ́! A yàn láti sin Olúwa."

22 Lẹ́yìn náà ni Joṣua , "̀yin ni ẹlẹ́rìí ara yín , ti yàn láti sin Olúwa."

Wọ́n dáhùn , "Bẹ́̀ ni, àwa ni ẹlẹ́rìí."

23 Nígbà náà ni Joṣua dáhùn , "òrìṣà orílẹ̀-èdè mìíràn ń bẹ àárín yín kúrò, ki ọkàn yín padà Olúwa, Ọlọ́run Israẹli."

24 Àwọn ènìyàn náà fún Joṣua , "Olúwa Ọlọ́run nìkan ni àwa yóò máa sìn, òun nìkan ni àwa yóò máa ṣe ìgbọ́ràn ."

25 ọjọ́ náà Joṣua májẹ̀fún àwọn ènìyàn, ó fi òfin àti ìlànà fún wọn Ṣekemu. 26 Joṣua kọ gbogbo ìdáhùn àwọn ènìyàn wọ̀nyí inú Ìwé Òfin Ọlọ́run. Lẹ́yìn náà ó gbé òkúta ńlá kan, ó gbé e kalẹ̀ abẹ́ igi óákù ̀ibi mímọ́ Olúwa.

27 "E ó!" ó fún gbogbo ènìyàn , "Òkúta yìí ni yóò jẹ́ ẹlẹ́rìí fún wa, nítorí ó ti gbọ́ gbogbo ̀rọ̀ Olúwa ti sọ fún wa. Yóò jẹ́ ẹlẹ́rìí yín ṣe àìṣòótọ́ Ọlọ́run yín."

28 Lẹ́yìn náà ni Joṣua jẹ́ àwọn ènìyàn lọ, olúkúlùkù ilẹ̀ ìní rẹ̀.

Ikú Joṣua àti Eleasari

29 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, Joṣua ọmọ Nuni ìránṣẹ́ Olúwa, ẹni àádọ́ọdún. 30 Wọ́n sin ín ilẹ̀ ìní rẹ̀, Timnati Serah ni ilẹ̀ orí òkè Efraimu, ìhà àríwá òkè Gaaṣi.

31 Israẹli sin Olúwa gbogbo ọjọ́ ayé Joṣua àti gbogbo ọjọ́ àwọn àgbàgbà ó lẹ́yìn ikú rẹ̀ wọ́n gbogbo iṣẹ́ ńlá Olúwa ṣe fún Israẹli.

32 Egungun Josẹfu, èyí àwọn ọmọ Israẹli kúrò Ejibiti, ni wọ́n sin Ṣekemu ìpín ilẹ̀ Jakọbu fún ọgọ́rùn-ún fàdákà ọwọ́ Hamori, baba Ṣekemu. Èyí jẹ́ ilẹ̀ ìní àwọn ọmọ Josẹfu.

33 Eleasari ọmọ Aaroni , wọ́n sin ín Gibeah, a ti pín fún ọmọ rẹ̀ Finehasi òkè ilẹ̀ Efraimu.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-