Publicidade

Atos 7

̀rọ̀ Stefanu àwọn àjọ ìgbìmọ̀

1 Nígbà náà ni olórí àlùfáà , "Òtítọ́ ha ni àwọn ̀sùn wọ́ fi kàn ́ ?"

2 ìdáhùn èyí ó , "̀yin arákùnrin àti ̀yin baba, fetísílẹ̀ mi! Ọlọ́run ògo fi ara hàn fún Abrahamu baba wa, nígbà ó ni Mesopotamia, ó to ṣe àtìpó ni Harani. 3 Ọlọ́run fún un , Jáde kúrò orílẹ̀-èdè rẹ àti kúrò lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ, lọ ilẹ̀ kan èmi yóò fihàn ́.’

4 "Nígbà náà ni ó jáde kúrò ilẹ̀ àwọn ará Kaldea, ó ṣe àtìpó ni Harani. Lẹ́yìn ìgbà baba rẹ̀ , Ọlọ́run un sípò padà ilẹ̀ yìí, níbi ̀yin ń gbé báyìí. 5 fún un ni ìní kan, ànító bi ìwọ̀n ààyè ẹsẹ̀ kan. Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ṣe ìlérí fún , òun yóò fi ilẹ̀ ìní náà fún un àti fún àwọn irú-ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀, nígbà ì ọmọ. 6 Ọlọ́run sọ báyìí , Irú-ọmọ rẹ yóò ṣe àtìpó ilẹ̀ àjèjì; wọn ó sọ wọn di ẹrú, wọn ó pọ́n wọn lójú fún irinwó (400) ọdún. 7 Ọlọ́run , Orílẹ̀-èdè náà wọn yóò máa sìn, ni èmi ó lẹ́jọ́; lẹ́yìn náà ni wọn ó jáde kúrò, wọn ó sìn níhìn-ín yìí.8 Ó fún Abrahamu ni májẹ̀ìkọlà. Abrahamu Isaaki, ó kọ ́ ilà ni ọjọ́ kẹjọ ó i. Isaaki Jakọbu, Jakọbu àwọn baba ńlá méjìlá.

9 "Àwọn baba ńlá ṣe ìlara Josẹfu, wọ́n á Ejibiti; ṣùgbọ́n Ọlọ́run pẹ̀rẹ̀, 10 ó yọ ́ kúrò nínú ìpọ́njú rẹ̀ gbogbo. Ó fún Josẹfu ọgbọ́n, ó ó ojúrere Farao ọba Ejibiti; òun fi jẹ baálẹ̀ Ejibiti àti gbogbo ilé rẹ̀.

11 "Ìyàn kan ni gbogbo ilẹ̀ Ejibiti àti ni Kenaani, àti ìpọ́njú ńlá, àwọn baba wa oúnjẹ. 12 Ṣùgbọ́n nígbà Jakọbu gbọ́ alikama ń bẹ ni Ejibiti, ó rán àwọn baba wa lọ lẹ́̀kínní. 13 Nígbà kejì Josẹfu fi ara rẹ̀ hàn fún àwọn arákùnrin rẹ̀, a tún fi wọ́n hàn fún Farao. 14 Lẹ́yìn èyí, Josẹfu ránṣẹ́ pe Jakọbu baba rẹ̀, àti àwọn ìbátan rẹ̀ sọ́dọ̀ rẹ, gbogbo wọ́n àrùndínlọ́gọ́rin ọkàn. 15 Nígbà náà ni Jakọbu sọ̀kalẹ̀ lọ Ejibiti, ibi òun àti àwọn baba wa . 16 A gbé òkú wọn padà Ṣekemu, a tẹ́ wọn sínú ibojì ti Abrahamu ni ọwọ́ àwọn ọmọ Amori Ṣekemu iye owó wúrà kan.

17 "Nígbà àkókò Ọlọ́run yóò ìlérí ó ṣe fún Abrahamu ṣẹ dẹ̀dẹ̀, àwọn ènìyàn wa ń gbèrú si gidigidi iye ilẹ̀ Ejibiti. 18 Ṣùgbọ́n ọba tuntun mìíràn mọ Josẹfu jẹ ilẹ̀ Ejibiti. 19 Òun náà ni ó ṣe àrékérekè àwọn ìbátan wa. Wọn hùwà búburú àwọn baba wa, bẹ́̀ wọ́n fi àwọn ọmọ ọwọ́ wọn kúrò lọ́wọ́ wọn nítorí wọn ṣe .

20 "àkókò náà ni a Mose ọmọ ó se iyebíye, wọn bọ́ lóṣù mẹ́ta ni ilé baba rẹ̀. 21 Nígbà wọn gbe é sọnù, ọmọbìnrin Farao gbé e, ó tọ ́ dàgbà gẹ́gẹ́ ọmọ ara rẹ̀. 22 A kọ́ Mose ni gbogbo ọgbọ́n ara Ejibiti, ó pọ̀ ni ̀rọ̀ àti ìṣe.

23 "Nígbà Mose di ọmọ ogójì ọdún, ó sọ i lọ́kàn láti lọ bẹ àwọn ọmọ Israẹli ará rẹ̀ . 24 Nígbà ó ̀kan nínú wọ́n ará Ejibiti kan ń jẹ́ ìyà, ó gbèjà rẹ̀, ó gbẹ̀san ẹni wọ́n jẹ ìyà nípa lílu ará Ejibiti náà pa. 25 Mose àwọn ará òun mọ̀ Ọlọ́run yóò ti ọwọ́ òun gbà wọn; ṣùgbọ́n wọn mọ̀. 26 ọjọ́ kejì Mose yọ àwọn ọmọ Israẹli méjì wọ́n ti ń . Òun si fẹ́ parí ìjà fún wọn. Ó , Ènìyàn mi, ará ni ̀yin; èéṣe ̀yin fi ń ṣe ohun tọ́ ara yín?

27 "Ṣùgbọ́n ẹni ó fínràn ẹnìkejì rẹ̀ ti Mose ̀gbẹ́ kan, ó , Ta ni ó fi ́ jẹ olórí àti onídàájọ́ lórí wa? 28 Ṣé ìwọ fẹ́ pa o ti pa ará Ejibiti lánàá?29 Mose nítorí ̀rọ̀ yìí, ó wa ṣe àtìpó ni ilẹ̀ Midiani, níbi ó gbé ọmọ méjì.

30 "Nígbà ogójì ọdún , angẹli Olúwa fi ara han Mose ijù, òkè Sinai, nínú ̀wọ́-iná nínú igbó. 31 Nígbà Mose i, ẹnu á ìran náà; nígbà ó súnmọ́ ọn láti ó fín, ohùn Olúwa kọ i, 32 Èmi ni Ọlọ́run àwọn baba rẹ, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki, àti Ọlọ́run Jakọbu,Mose wárìrì pẹ̀ìbẹ̀, dáṣà láti ó mọ́.

33 "Olúwa fún un , Bọ́ bàtà rẹ kúrò ẹsẹ̀ rẹ, nítorí ibi ìwọ dúró i ilẹ̀ mímọ́ ni. 34 , mo ti ìpọ́njú àwọn ènìyàn mi ń bẹ ni Ejibiti, mo ti gbọ́ ìkérora wọn, mo sọ̀kalẹ̀ láti gbà wọ́n. nísinsin yìí, Èmi ó rán lọ ilẹ̀ Ejibiti.

35 "Mose náà yìí wọ́n kọ̀, , Ta ni ó fi jẹ olórí àti onídàájọ́?’ Òun náà ni Ọlọ́run rán lọ láti ọwọ́ angẹli, ó farahàn án pápá, láti ṣe olórí àti olùdáǹdè. 36 Òun ni ó wọn jáde, lẹ́yìn ìgbà ó ṣe iṣẹ́ ìyanu àti iṣẹ́ àmì ilẹ̀ Ejibiti, àti ni Òkun pupa, àti ni aginjù ogójì ọdún.

37 "Èyí ni Mose náà ti ó fún àwọn ọmọ Israẹli , Ọlọ́run yóò gbé wòlíì kan èmi dìde nínú àwọn ènìyàn yín.38 Èyí náà ni ẹni ó nínú ìjọ ijù pẹ̀angẹli náà ó a sọ̀rọ̀ orí òkè Sinai, àti pẹ̀àwọn baba wa; ẹni ti ó gba ̀rọ̀ ìyè láti fi fún wa.

39 "Ṣùgbọ́n àwọn baba wa fẹ́ gbọ́ tirẹ̀. Dípò bẹ́̀, wọ́n kọ̀ ́ sílẹ̀, àti nínú ọkàn wọn, wọn fẹ́ yípadà lọ ilẹ̀ Ejibiti. 40 Wọ́n fún Aaroni , òrìṣà fún wa yóò máa tọ́ṣáájú wa; nítorí ó ṣe ti Mose yìí ó wa jáde láti ilẹ̀ Ejibiti, a mọ̀ ohun ó ṣe é.41 Wọ́n ère ẹgbọrọ màlúù ni ọjọ́ wọ̀nyí. Wọ́n ẹbọ ère náà, wọ́n ń yọ̀ nínú ohun wọ́n fi ọwọ́ ara wọn ṣe. 42 Ọlọ́run padà, ó fi wọn sílẹ̀ láti máa sin ogun ̀run: òòrùn, òṣùpá àti ìràwọ̀. Èyí ìbámu pẹ̀a ti kọ ́ nínú ìwé àwọn wòlíì :

" ̀yin ha ẹran a pa àti ẹbọ wa fún mi

ogójì ọdún ijù , ìwọ ilé Israẹli?

43 ̀yin tẹ́wọ́gbà àgọ́ Moleki,

àti ìràwọ̀ Refani òrìṣà yín,

àwòrán ̀yin ṣe láti máa bọ wọ́n.

Nítorí náà èmi yóò yín lọ ìgbèkùn rékọjá Babeli.

44 "Àwọn baba wa àgọ́ ̀pẹ̀wọn ijù. Èyí a ṣe gẹ́gẹ́ Ọlọ́run ó ba Mose sọ̀rọ̀ ó ṣe é, gẹ́gẹ́ àpẹẹrẹ ó ti . 45 Ti àwọn baba wa ó tẹ̀wọn Joṣua ilẹ̀ ìní àwọn aláìkọlà, Ọlọ́run jáde kúrò níwájú àwọn baba wa, títí àkókò Dafidi. 46 Ẹni ó ojúrere níwájú Ọlọ́run, ó tọrọ láti ibùgbé fún Ọlọ́run Jakọbu. 47 Ṣùgbọ́n Solomoni ni ó kọ́ ilé fún un.

48 "Ṣùgbọ́n ̀gá-ògo í gbé ilé ti a fi ọwọ́ kọ́, gẹ́gẹ́ wòlíì ti :

49 " ̀run ni ìtẹ́ mi,

ayé ni àpótí ìtìsẹ̀ mi.

Irú ilé kín ̀yin yóò kọ́ fún mi?

ni Olúwa .

Tàbí níbo ni yóò jẹ́ ibi ìsinmi mi?

50 Ọwọ́ mi ha ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí.

51 "̀yin ọlọ́rùn líle àti aláìkọlà àyà àti etí! àwọn baba yín gẹ́lẹ́ ni ̀yin . Nígbà gbogbo ni ̀yin máa ń dènà ̀Mímọ́! 52 Ǹjẹ́ ̀kan tilẹ̀ nínú àwọn wòlíì àwọn baba yín ṣe inúnibíni ? Wọn ti pa àwọn ti ó ti ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa wíwá Ẹni Olódodo náà. Nísinsin yìí ̀yin ti dalẹ̀ rẹ̀ ̀yin ti pa. 53 ̀yin ó gba òfin, gẹ́gẹ́ àwọn angẹli ti fi fún ni, pa á mọ́."

A sọ Stefanu òkúta pa

54 Nígbà wọn gbọ́ nǹkan wọ̀nyí ọkàn wọn gbọgbẹ́ inú, wọn payínkeke i. 55 Ṣùgbọ́n Stefanu, ẹni ó kún fún ̀Mímọ́, ó tẹjúmọ́ ̀run, ó ògo Ọlọ́run, àti Jesu dúró ọwọ́ ̀tún Ọlọ́run. 56 Ó , "ó, mo ̀run ṣí sílẹ̀, Ọmọ Ènìyàn dúró ọwọ́ ̀tún Ọlọ́run."

57 Nígbà náà ni wọn kígbe ohùn rara, wọn di etí wọ́n, gbogbo wọn sáré i, wọ́n rọ́ ú, 58 wọ́n wọ́ sẹ́yìn òde ìlú, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sísọ ́ òkúta; àwọn ẹlẹ́rìí fi aṣọ wọn lélẹ̀ lẹ́sẹ̀ ọmọkùnrin kan a ń Saulu.

59 wọ́n ti ń sọ Stefanu òkúta, ó pe Olúwa , "Jesu Olúwa, gba ̀mi." 60 Nígbà náà ni ó wólẹ̀ lórí eékún rẹ̀, ó kígbe sókè , "Olúwa, ṣe ka ̀ṣẹ̀ yìí wọn ọrùn." Nígbà ti ó èyí tán, ó sùn lọ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-