Publicidade

Jeremias 32

Jeremiah ra pápá kan

1 Èyí ni ̀rọ̀ tọ Jeremiah láti ̀dọ̀ Olúwa ọdún kẹwàá Sedekiah ọba Juda, èyí ó jẹ́ ọdún kejìdínlógún ti Nebukadnessari. 2 Àwọn ogun ọba Babeli ìgbà náà Jerusalẹmu mọ́. A wòlíì Jeremiah mọ́ inú túbú wọ́n ń ṣọ́ àgbàlá ilé ọba Juda.

3 Nítorí Sedekiah ọba Juda ti a mọ́síbẹ̀; , "ìwọ fi ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ bẹ́̀? o , Báyìí ni Olúwa : Èmi ń bọ̀ fi ìlú yìí fún ọba Babeli, yóò gbà á. 4 Sedekiah ọba Juda bọ́ lọ́wọ́ àwọn Kaldea, ṣùgbọ́n à ó fún ọba Babeli, yóò sọ̀rọ̀ ojúkojú; yóò pẹ̀ojú rẹ̀. 5 Yóò Sedekiah lọ Babeli yóò títí èmi yóò fi bẹ̀ ́ ni Olúwa . ̀yin àwọn ará Kaldea , ̀yin yóò borí wọn.’ "

6 Jeremiah , "̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 7 Hanameli ọmọkùnrin Ṣallumu ̀gbọ́n rẹ̀ yóò tọ̀ ́ , Ra pápá mi ó Anatoti; nítorí gẹ́gẹ́ ẹni súnmọ́ wọn, ̀tọ́ àti ìṣe rẹ láti á.

8 "Gẹ́gẹ́ Olúwa ti sọ, Hanameli ọmọ ̀gbọ́n mi tọ̀ àgbàlá túbú , Ra pápá mi ó Anatoti ó ilẹ̀ Benjamini, èyí ó jẹ́ ̀tọ́ rẹ ni láti gbà á àti láti ni, á fún ara rẹ.

"Nígbà náà ni èmi mọ̀ ̀rọ̀ Olúwa ni èyí. 9 Bẹ́̀ ni; èmi ra pápá náà Anatoti láti ọwọ́ Hanameli ọmọ ̀gbọ́n mi. Mo wọn ìwọ̀n ṣékélì àti fàdákà mẹ́tàdínlógún fún un. 10 Mo fọwọ́ sínú ìwé, mo í pa. Mo pe ẹlẹ́rìí i, mo wọn fàdákà náà lórí òsùwọ̀n. 11 Mo ìwé mo fi á, èyí a di pa nípa àṣẹ àti òfin wa, àti èyí a lẹ̀. 12 Èmi fi èyí fún Baruku, ọmọ Neriah, ọmọ Maseiah, ojú Hanameli, ọmọ ̀gbọ́n mi àti níwájú àwọn ẹlẹ́rìí ó ti fi ọwọ́ ìwé àti ojú àwọn Júù gbogbo wọ́n jókòó àgbàlá ilé túbú.

13 "ojú wọn ni èmi ti pàṣẹ fún Baruku , 14 èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli ; àwọn ìwé a fi á wọ̀nyí, àti èyí a lẹ̀ àti èyí a lẹ̀, o gbé wọn sínú ìkòkò amọ̀, wọn ó ọjọ́ púpọ̀. 15 Nítorí èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli ; àwọn ilẹ̀, pápá àti ọgbà àjàrà ni à ó tún padà nílẹ̀ yìí.

16 "Lẹ́yìn mo ti fi ìwé rírà náà fún Baruku ọmọkùnrin Neriah, mo gbàdúrà Olúwa :

17 "Háà! Olúwa Olódùmarè, ìwọ o ̀run àti ayé pẹ̀títóbi agbára rẹ àti gbogbo ̀rọ̀ apá rẹ. ohun ó ṣòro fún láti ṣe. 18 O fi ìfẹ́ hàn ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn ènìyàn, ṣùgbọ́n o gbé ìyà ̀ṣẹ̀ àwọn baba àwọn ọmọ lẹ́yìn wọn. Ọlọ́run títóbi àti alágbára, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ. 19 Títóbi ni ìgbìmọ̀, àti alágbára í ṣe, ojú rẹ̀ ṣì gbogbo ̀àwọn ọmọ ènìyàn; láti fi fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ ̀rẹ̀ àti gẹ́gẹ́ èso iṣẹ́ rẹ̀. 20 O ṣe iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu ńlá Ejibiti. O ń ṣe é títí di òní Israẹli àti lára ọmọ ènìyàn ó ti gba òkìkí ó jẹ́ tìrẹ. 21 O àwọn Israẹli ènìyàn rẹ jáde láti Ejibiti pẹ̀iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu nínú ọwọ́ agbára àti nína apá rẹ pẹ̀̀ńlá. 22 Ìwọ fún wọn nílẹ̀ yìí, èyí o ti ṣèlérí fún àwọn baba ńlá wọn; ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin. 23 Wọ́n , wọ́n gba ilẹ̀ náà ṣùgbọ́n wọn gbọ́ ̀rọ̀ rẹ tàbí tẹ̀òfin rẹ. Wọn ṣe ohun o pàṣẹ fún wọn, nítorí náà ìwọ àwọn ibi yìí sórí wọn.

24 "ó, àwọn ìdọ̀ṣe kórajọ láti gba ìlú. Nítorí idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn, fi ìlú ọwọ́ àwọn ará Kaldea ń gbóguntì wọ́n. Ohun ìwọ sọ ṣẹ gẹ́gẹ́ o ṣe i. 25 Síbẹ̀ a ó fi ìlú náà fún àwọn ará Babeli, ìwọ Olúwa Olódùmarè sọ fún mi , Ra pápá náà pẹ̀owó fàdákà, o pe ẹlẹ́rìí.’ "

26 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah : 27 "Èmi ni Olúwa Ọlọ́run gbogbo ẹran-ara. Ǹjẹ́ ohun kan ha a ṣòro fún mi ? 28 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa , Èmi ṣetán láti fi ìlú yìí fún àwọn ará Kaldea àti fún Nebukadnessari ọba Babeli ẹni yóò o. 29 Àwọn ará Kaldea ó ń gbógun ìlú yóò wọ ìlú. Wọn ó fi iná ìlú; wọn ó o palẹ̀ pẹ̀ilé àwọn ènìyàn ti ń mi bínú, wọ́n ń ẹbọ tùràrí lórí pẹpẹ fún Baali tiwọn ń da ẹbọ ohun mímu fún àwọn ọlọ́run mìíràn.

30 "Àwọn ènìyàn Israẹli àti Juda ṣe ohun kankan ṣe ibi lójú mi láti ìgbà èwe wọn. Nítorí àwọn ọmọ Israẹli ti fi kìkì iṣẹ́ ọwọ́ wọ́n mi bínú ni Olúwa . 31 Láti ọjọ́ wọ́n ti kọ́ , títí di àkókò yìí ni ìlú yìí ti jẹ́ ohun ìbínú àti ìyọnu fún mi bẹ́̀ èmi yóò á tu kúrò níwájú mi. 32 Àwọn ènìyàn Israẹli àti àwọn ènìyàn Juda ti mi bínú pẹ̀gbogbo ìbàjẹ́ wọ́n ṣe. Àwọn Israẹli, ọba wọn àti gbogbo ìjòyè, àlùfáà àti wòlíì, àwọn ọkùnrin Juda àti àwọn ènìyàn Jerusalẹmu. 33 Wọ́n kọ ̀yìn mi, wọ́n ojú wọn padà. Èmi kọ wọ́n, síbẹ̀ wọn fetísílẹ̀ láti gbọ́ ̀kọ́ tàbí kọbi ara ìwà ìbàjẹ́. 34 Wọ́n òrìṣà ìríra wọn jọ inú ilé wọ́n fi orúkọ mi , wọ́n ṣọ́ di àìmọ́. 35 Wọ́n kọ́ ibi gíga fún Baali àfonífojì Hinnomu láti fi ọmọ wọn ọkùnrin àti obìnrin ẹbọ Moleki. Èmi pàṣẹ, fún wọn, bẹ́̀ ni ọkàn mi wọ́n ṣe ohun ìríra wọ̀nyí ó Juda dẹ́ṣẹ̀.

36 "Ìwọ ń sọ̀rọ̀ nípa ti ìlú yìí , Pẹ̀idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn ni à ó fi wọ́n fún ọba Babeli,ṣùgbọ́n ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ nìyìí, 37 Èmi ó wọn jọ láti gbogbo ilẹ̀ mo ti wọn kúrò ìgbà ìbínú àti ìkáàánú ńlá mi. Èmi yóò wọn padà ilẹ̀ yìí; èmi ó jẹ́ wọn ó máa gbé láìléwu. 38 Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi, èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run wọn. 39 Èmi ó fún wọn ọkàn kan àti ìṣe wọn ó máa bẹ̀mi fún rere wọn àti fún rere àwọn ọmọ wọn ó tẹ̀wọn. 40 Èmi ò wọn májẹ̀ayérayé, èmi dúró láti ṣe rere fún wọn, Èmi ó jẹ́ wọ́n bẹ̀mi, wọn yóò padà lẹ́yìn mi. 41 Lóòtítọ́, èmi ó yọ̀ nípa ṣíṣe wọ́n rere, èmi ó fi wọn lójú nípa gbígbìn wọ́n ilẹ̀ yìí tọkàntọkàn mi.

42 "Nítorí báyìí ni Olúwa , gẹ́gẹ́ èmi ti gbogbo ibi ńlá yìí sórí àwọn ènìyàn yìí, bẹ́̀ ni èmi ó gbogbo rere èmi ti sọ nípa tiwọn sórí wọn. 43 Lẹ́̀kan i, pápá yóò di rírà ilẹ̀ yìí ìwọ ti sọ , Ohun òfò ni ọkùnrin tàbí àwọn ẹran, nítorí a ti fi fún àwọn ará Babeli.44 Wọn ó fi owó fàdákà ra oko, wọn yóò fi ọwọ́ ìwé, wọn ó pa pẹ̀ẹlẹ́rìí láti ilẹ̀ Benjamini àti ìlú kéékèèké ó Jerusalẹmu , àti ìlú Juda àti ìlú àwọn ìlú orí òkè, àti ni àwọn ẹsẹ̀ òkè, àti gúúsù, èmi ó ìgbèkùn wọn padà , ni Olúwa ."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-