Publicidade

1 Coríntios 3

Lórí ìyapa nínú ìjọ

1 Ará, èmí le yín sọ̀rọ̀ àwọn í ṣe ti ̀, ṣe àwọn ti í ṣe ti ara, àní àwọn ọmọ ọwọ́ nínú Kristi. 2 Wàrà ni mo ti fi bọ́ yín, í ṣe oúnjẹ; nítorí í le gbà á nísinsin yìí náà, í le gbà a. 3 Nítorí ̀yin jẹ́ ti ara síbẹ̀. Nítorí, níwọ̀n owú jíjẹ àti ìjà ṣe láàrín ara yín, ̀yin ha ṣe ti ayé ? ̀yin ha ṣe ènìyàn lásán ? 4 Ǹjẹ́ ̀yin í ṣe ènìyàn lásán ? Níwọ́n ìgbà ba ń sọ , "Èmi ń tẹ̀Paulu," àti ti ẹlòmíràn tún , "Èmi ń tẹ̀Apollo."

5 gbogbo rẹ̀ lọ, ni Apollo ha jẹ́, kín ni Paulu jẹ́, àwọn ìránṣẹ́ lásán, nípasẹ̀ ẹni ̀yin gbàgbọ́, gẹ́gẹ́ Olúwa ti fi fún olúkúlùkù. 6 Èmi gbìn, Apollo ń bomirin; ṣùgbọ́n Ọlọ́run ni ń ìbísí . 7 Ǹjẹ́ í ṣe ẹni ó ń gbìn nǹkan kan, bẹ́̀ ni í ṣe ẹni ń bomirin; ṣe Ọlọ́run ó ń ìbísí . 8 Ẹni ó ń gbìn àti ẹni ó ń bu omi rín ìrònú kan àti èrèdí kan, ó tilẹ̀ jẹ́ ẹnìkọ̀̀kan wa yóò gba èrè tirẹ̀, gẹ́gẹ́ ó ti ṣe é kárakára . 9 A ń Ọlọ́run ṣiṣẹ́ pọ̀ ni, ̀yin pàápàá jẹ́ ọgbà ohun ̀gbìn fún Ọlọ́run, í ṣe fún wa, ilé Ọlọ́run ni yín, í ṣe ilé tiwa.

10 Nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run fi fún mi, gẹ́gẹ́ ọlọ́gbọ́n ̀mọ̀, mo ti fi ìpìlẹ̀ ilé lélẹ̀, ẹlòmíràn ń mọ e, ṣùgbọ́n olúkúlùkù kíyèsára yóò ṣe mọ ́n e. 11 Nítorí ẹlòmíràn le fi ìpìlẹ̀ tòótọ́ mìíràn lélẹ̀ ju èyí a fi lélẹ̀ àní Jesu Kristi ni ìpìlẹ̀ náà. 12 Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni fi wúrà, fàdákà, òkúta olówó-iyebiye, igi, koríko, àgékù koríko mọ orí ìpìlẹ̀ yìí. 13 Iṣẹ́ olúkúlùkù ènìyàn yóò hàn, nítorí ọjọ́ náà yóò fi í hàn, nítorí nínú iná ni a ó ti fihàn, iná náà yóò dán irú iṣẹ́ èyí olúkúlùkù ṣe . 14 iṣẹ́ ẹnikẹ́ni ṣe lórí rẹ̀ dúró, òun yóò gba èrè rẹ̀. 15 iṣẹ́ ẹnikẹ́ni jóná, òun yóò pàdánù, ṣùgbọ́n òun tìkára rẹ̀ ni a ó gbàlà, ṣùgbọ́n ìgbà ènìyàn la àárín iná kọjá.

16 Ṣé ̀yin tilẹ̀ mọ̀ tẹmpili Ọlọ́run ni ̀yin jẹ́? Àti pẹ̀pe ̀Ọlọ́run ń gbé inú yín? 17 ẹnikẹ́ni ba tẹmpili Ọlọ́run jẹ́, òun ni Ọlọ́run yóò parun; nítorí mímọ́ ni tẹmpili Ọlọ́run, èyí ̀yin jẹ́.

18 ẹnikẹ́ni, ṣe tan ara rẹ̀ jẹ mọ́. ẹnikẹ́ni yín nínú ayé yìí ba òun gbọ́n, jẹ́ ó di òmùgọ̀ ó a le è gbọ́n. 19 Nítorí ọgbọ́n ayé yìí jẹ́ òmùgọ̀ lọ́dọ̀ Ọlọ́run. Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ nínú Ìwé Mímọ́ , "Ẹni ti ó mu àwọn ọlọ́gbọ́n nínú àrékérekè wọn"; 20 lẹ́̀kan i, "Olúwa mọ̀ èrò inú àwọn ọlọ́gbọ́n asán wọn." 21 Nítorí ẹnikẹ́ni ṣe ṣògo nínú ènìyàn. Nítorí yín ni ohun gbogbo. 22 Ìbá ṣe Paulu, tàbí Apollo, tàbí Kefa, tàbí ayé tàbí ìyè, tàbí ikú, tàbí ohun ìsinsin yìí, tàbí ohun ìgbà ń bọ̀; tiyín ni gbogbo wọn. 23 ̀yin ni ti Kristi; Kristi ni ti Ọlọ́run.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-