Publicidade

Apocalipse 11

Àwọn ẹlẹ́rìí méjì

1 11.1: El 40.3. A fi ìfèéfèé kan fún mi o dàbí ̀pá-ìwọ̀n: ẹnìkan , "Dìde, wọn tẹmpili Ọlọ́run, àti pẹpẹ, àti àwọn ń sìn nínú rẹ̀. 2 11.2: Sk 12.3; Isa 63.18; Lk 21.24.fi àgbàlá ń bẹ lóde tẹmpili sílẹ̀, ṣe wọ́n ́n; nítorí a fi fún àwọn aláìkọlà: ìlú mímọ́ náà ni wọn ó tẹ̀ mọ́lẹ̀ oṣù méjìlélógójì (42). 3 Èmi ó yọ̀ǹda fún àwọn ẹlẹ́rìí mi méjèèje, wọn ó sọtẹ́lẹ̀ fún ẹgbẹ̀ọjọ́ ó ọgọ́ta (1,260) nínú aṣọ ̀fọ̀." 4 11.4: Sk 4.3,11-14.Wọ̀nyí ni igi olifi méjì náà, àti ̀fìtílà méjì náà ń dúró níwájú Olúwa ayé. 5 11.5: 2Ọb 1.10; Jr 5.14.ẹnikẹ́ni fẹ́ pa wọn lára, iná ó ti ẹnu wọn jáde, a pa àwọn ̀wọn run, báyìí ni a ó pa ẹnikẹ́ni ó ba ń fẹ́ pa wọn lára run. 6 11.6: 1Ọb 17.1; Ek 7.17,19.Àwọn wọ̀nyí ni ó ni agbára láti ̀run, òjò fi rọ̀ ni ọjọ́ àsọtẹ́lẹ̀ wọn. Wọ́n agbára lórí omi láti sọ wọn di ̀jẹ̀, àti láti fi onírúurú àjàkálẹ̀-ààrùn kọlu ayé, nígbàkígbà wọ́n fẹ́.

7 11.7: Da 7.3,7,21. Nígbà wọn ti parí ̀wọn, ẹranko o ń inú ̀gbun gòkè yóò wọn jagun, yóò ṣẹ́gun wọn, yóò pa wọ́n. 8 11.8: Isa 1.9.Òkú wọn yóò ni ìgboro ìlú ńlá náà a ń Sodomu àti Ejibiti nípa ti ̀, níbi a gbé kan Olúwa wọ́n mọ́ àgbélébùú. 9 Fún ọjọ́ mẹ́ta àti ààbọ̀ ni àwọn ènìyàn nínú ènìyàn gbogbo àti ̀, àti èdè, àti orílẹ̀, wo òkú wọn, wọn si jẹ a gbé òkú wọn sínú ibojì. 10 Àti àwọn o ń gbé orí ilẹ̀ ayé yóò yọ̀ wọn lórí, wọn yóò ṣe àríyá, wọn ó ta ara wọn lọ́rẹ; nítorí àwọn wòlíì méjèèjì yìí àwọn o ń bẹ lórí ilẹ̀ ayé lóró.

11 11.11: El 37.5,10. Àti lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta àti ààbọ̀ náà, ̀ìyè láti ̀dọ̀ Ọlọ́run wọ inú wọn, wọn dìde dúró ni ẹsẹ̀ wọn; ̀ńlá ba àwọn o wọn. 12 11.12: 2Ọb 2.11.Wọn gbọ́ ohùn ńlá kan láti ̀run ń fún wọn , "gòkè ìhín!" Wọn gòkè lọ ̀run nínú ìkùùkuu àwọsánmọ̀; lójú àwọn ̀wọn.

13 wákàtí náà omìmì-ilẹ̀ ńlá kan , ìdámẹ́wàá ìlú náà , àti nínú omìmì-ilẹ̀ náà ̀́dẹ́gbàárin (7,000) ènìyàn a pa; ̀ba àwọn ìyókù, wọn fi ògo fún Ọlọ́run ̀run.

14 Ègbé kejì kọjá; kíyèsi i, ègbé kẹta ń bọ̀ kánkán.

Ìpè méje

15 11.15: Sm 22.28; Da 7.14,27. Angẹli keje fọn ìpè; a gbọ́ ohùn ńlá láti ̀run, ,

"Ìjọba ayé di ti Olúwa , àti Kristi rẹ̀;

òun yóò jẹ ọba láé àti láéláé!"

16 Àwọn àgbà mẹ́rìnlélógún náà wọn jókòó níwájú Ọlọ́run lórí ìtẹ́ wọn, dojúbolẹ̀, wọn sin Ọlọ́run, 17 :

"Àwa fi ọpẹ́ fún , Olúwa Ọlọ́run, Olódùmarè,

ń bẹ, ó ti ,

nítorí ìwọ ti gba agbára ńlá rẹ̀,

ìwọ ti jẹ ọba.

18 11.18: Sm 2.1. Inú àwọn orílẹ̀-èdè, bẹ́̀ ni ìbínú rẹ̀ ti ,

àti àkókò láti àwọn òkú lẹ́jọ́,

àti láti fi èrè fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ wòlíì,

àti àwọn ènìyàn mímọ́, àti àwọn o bẹ̀orúkọ rẹ̀,

àti ẹni kékeré àti ẹni ńlá;

àti láti run àwọn ń pa ayé run."

19 11.19: 1Ọb 8.1-6; 2. A ṣí tẹmpili Ọlọ́run sílẹ̀ ̀run, a ri àpótí májẹ̀nínú tẹmpili rẹ̀. Mọ̀nàmọ́kọ, a gbọ́ ohùn, àrá sán, ilẹ̀ mi, yìnyín ńlá bọ́.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-