Pular para o conteúdo
Publicidade

Apocalipse 15

Angẹli méje pẹ̀ìyọnu méje

1 15.1: Le 26.21. Mo àmì mìíràn ̀run ó tóbi ó ya ni lẹ́nu, àwọn angẹli méje ó ni àwọn ìyọnu méje ìkẹyìn, nítorí nínú wọn ni ìbínú Ọlọ́run òpin. 2 Mo ẹni , Òkun dígí o dàpọ̀ pẹ̀iná: àwọn ó dúró lórí Òkun dígí yìí jẹ́ àwọn ti wọ́n ṣẹ́gun ẹranko náà, àti àwòrán rẹ̀, àti àmì rẹ̀ àti nọ́mbà orúkọ rẹ̀, wọn ohun èlò orin Ọlọ́run. 3 15.3: Ek 15.1; Sm 145.17.Wọ́n ń kọ orin ti Mose, ìránṣẹ́ Ọlọ́run, àti orin ti ̀dọ́-Àgùntàn, :

"Títóbi àti ìyanu ni àwọn iṣẹ́ rẹ,

Olúwa Ọlọ́run Olódùmarè;

òdodo àti òtítọ́ ni ̀rẹ̀,

ìwọ ọba àwọn orílẹ̀-èdè.

4 15.4: Jr 10.7; Sm 86.9-10. Ta ni yóò bẹ̀, Olúwa,

yóò fi ògo fún orúkọ rẹ̀?

Nítorí ìwọ nìkan ṣoṣo ni mímọ́.

Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ni yóò ,

ti yóò foríbalẹ̀ níwájú rẹ,

nítorí a ti fi ìdájọ́ rẹ hàn."

5 15.5: Ek 40.34. Lẹ́yìn náà mo wo, kíyèsi i, a ṣí tẹmpili àgọ́ ̀̀run sílẹ̀; 6 àwọn angẹli méje náà ti inú tẹmpili jáde , wọ́n ni ìyọnu méje náà, a wọ̀ wọ́n aṣọ ̀gbọ̀ funfun ti ń dán, a fi àmùrè wúrà dìwọ́n ni oókan àyà. 7 Àti ̀kan nínú àwọn ̀alààyè mẹ́rin náà fi ìgò wúrà méje fún àwọn angẹli méje náà, ó kún fún ìbínú Ọlọ́run, ẹni ń bẹ láààyè láé àti láéláé. 8 Tẹmpili náà kún fún èéfín láti inú ògo Ọlọ́run àti agbára rẹ̀ ; ẹnikẹ́ni wọ inú tẹmpili náà lọ títí a fi ìyọnu méjèèje àwọn angẹli méje náà ṣẹ.

Veja também