Publicidade

Apocalipse 20

Ìjọba ẹgbẹ̀rún ọdún

1 Mo angẹli kan ń ti ̀run sọ̀kalẹ̀ , ti òun ti kọ́kọ́rọ́ ̀gbun, àti ̀wọ̀n ńlá kan ọwọ́ rẹ̀. 2 O di dragoni náà , ejò àtijọ́ , í ṣe èṣù, àti Satani, ó é ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún. 3 Ó gbé e sọ sínú ̀gbun náà, ó í, ó fi èdìdì í lórí rẹ̀, ó ba à tan àwọn orílẹ̀-èdè jẹ mọ́ títí ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún náà yóò fi . Lẹ́yìn èyí, a le ṣàì u sílẹ̀ fún ìgbà díẹ̀.

4 20.4: Da 7.9,22,27. Mo àwọn ìtẹ́, wọ́n jókòó lórí wọn, a fi ìdájọ́ fún wọ́n, mo ọkàn àwọn a ti bẹ́ lórí nítorí ̀Jesu, àti nítorí ̀rọ̀ Ọlọ́run, àti àwọn foríbalẹ̀ fún ẹranko náà, àti fún àwòrán rẹ̀, tàbí gbà àmì rẹ̀ iwájú wọn àti ọwọ́ wọn; wọ́n láààyè, wọ́n jẹ ọba pẹ̀Kristi ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún. 5 (Àwọn òkú ìyókù láààyè mọ́ títí ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún náà yóò fi ). Èyí ni àjíǹde èkínní. 6 Ẹni ìbùkún àti mímọ́ ni ẹni ó ipa nínú àjíǹde èkínní náà. Lórí àwọn wọ̀nyí ikú ̀̀kejì agbára, ṣùgbọ́n wọn ó jẹ́ àlùfáà Ọlọ́run àti ti Kristi, wọn ó máa jẹ ọba pẹ̀rẹ̀ ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún.

Ìparun Satani

7 Nígbà ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún náà , a ó Satani sílẹ̀ kúrò nínú túbú rẹ̀. 8 20.8: El 38.2,9,15.Yóò jáde lọ láti máa tan àwọn orílẹ̀-èdè ń bẹ igun mẹ́rẹ̀̀rin ayé jẹ, Gogu àti Magogu, láti gbá wọn jọ ogun: àwọn iyè wọn dàbí iyanrìn Òkun. 9 20.9: 2Ọb 1.10-12.Wọ́n gòkè lọ la ibú ayé , wọ́n ibùdó àwọn ènìyàn mímọ́ àti ìlú àyànfẹ́ náà: iná ti ̀run sọ̀kalẹ̀ , ó wọn run. 10 A wọ́ Èṣù ó tàn wọ́n jẹ lọ sínú adágún iná àti sulfuru, níbi ẹranko àti wòlíì èké gbé , a ó máa wọn lóró tọ̀sán tòru láé àti láéláé.

Àwọn òkú gba ìdájọ́

11 20.11-12: Da 7.9-10. Mo ìtẹ́ funfun ńlá kan, àti ẹni ó jókòó lórí rẹ̀, níwájú ẹni ayé àti ̀run lọ; a ààyè fún wọn mọ́. 12 Mo àwọn òkú, àti èwe àti àgbà, wọn dúró níwájú ìtẹ́; a ṣí àwọn ìwé sílẹ̀; a ṣí àwọn ìwé mìíràn kan sílẹ̀ í ṣe ìwé ìyè: a ṣe ìdájọ́ fún àwọn òkú láti inú ohun a ti kọ sínú àwọn ìwé náà, gẹ́gẹ́ iṣẹ́ wọn. 13 Òkun jọ̀wọ́ àwọn òkú ń bẹ nínú rẹ̀ lọ́wọ́; àti òkú àti ipò òkú jọ̀wọ́ òkú ó nínú wọn pẹ̀: a ṣe ìdájọ́ wọn, olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ wọn. 14 Àti ikú àti ipò òkú ni a sọ sínú adágún iná. Èyí ni ikú kejì. 15 20.15: If 3.5.a ẹnikẹ́ni a kọ orúkọ rẹ̀ sínú ìwé ìyè, a ó sọ ́ sínú adágún iná.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-