Pular para o conteúdo
Publicidade

Ìfihàn 22

Omi iyè

1 Ó fi odò omi ìyè kan hàn mi, ó mọ́ kirisitali, ń ibi ìtẹ́ Ọlọ́run àti ̀dọ́-Àgùntàn jáde , 2 22.2: Gẹ 2.9.àárín ìgboro rẹ̀, àti níhà èkínní kejì odò náà, ni igi ìyè gbé , o máa ń so onírúurú èso méjìlá, a máa so èso rẹ̀ ni oṣooṣù ewé igi náà fún mímú àwọn orílẹ̀-èdè láradà. 3 22.3: Sk 14.11.Ègún yóò ṣí mọ: ìtẹ́ Ọlọ́run àti ̀dọ́-àgùntàn ni yóò máa níbẹ̀; àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò máa sìn ín. 4 22.4: Sm 17.15.Wọ́n ó si máa ojú rẹ̀; orúkọ rẹ̀ yóò si máa ni iwájú orí wọn. 5 Òru yóò mọ́; wọn wa ìmọ́lẹ̀ fìtílà, tàbí ìmọ́lẹ̀ oòrùn; nítorí Olúwa Ọlọ́run ni yóò tan ìmọ́lẹ̀ fún wọn: wọn ó máa jẹ ọba láé àti láéláé.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também