Pular para o conteúdo
Publicidade

Apocalipse 9

1 Angẹli karùn-ún fún ìpè tirẹ̀, mo , ìràwọ̀ kan bọ́ sílẹ̀ láti ̀run , a fi kọ́kọ́rọ́ ihò ̀gbun fún un. 2 9.2: Gẹ 19.28; Ek 19.18; Jl 2.10.Ó ṣí ihò ̀gbun náà, èéfín jáde láti inú ihò náà , èéfín ìléru ńlá, oòrùn àti ojú sánmọ̀ ṣókùnkùn nítorí èéfín ihò náà. 3 9.3: Ek 10.12-15.Àwọn eṣú jáde ti inú èéfín náà sórí ilẹ̀, a fi agbára fún wọn gẹ́gẹ́ agbára àkéekèe ilẹ̀. 4 9.4: El 9.4.A fún wọn ki wọn ṣe pa koríko ilẹ̀ lára tàbí ohun tútù kan, tàbí igikígi kan; ṣe àwọn ènìyàn ni èdìdì Ọlọ́run iwájú wọn. 5 A pàṣẹ fún wọn , wọn ṣe pa wọ́n, ṣùgbọ́n a wọn ni oró ni oṣù márùn-ún, oró wọn dàbí oró àkéekèe, nígbà o ta ènìyàn. 6 9.6: Jb 3.21.ọjọ́ wọ̀nyí ni àwọn ènìyàn yóò máa ikú, wọn yóò i; wọn yóò fẹ́ láti , ikú yóò kúrò lọ́dọ̀ wọn.

7 9.7: Jl 2.4. Ìrísí àwọn eṣú náà dàbí àwọn ẹṣin a múra sílẹ̀ fún ogun; àti orí wọn ni ohun o dàbí àwọn adé wúrà , ojú wọn dàbí ojú ènìyàn; 8 9.8: Jl 1.6.wọ́n irun obìnrin, eyín wọn dàbí ti kìnnìún. 9 9.9: Jl 2.5.Wọ́n ìgbàyà ó dàbí ìgbàyà irin; ìró ìyẹ́ wọn dàbí ìró kẹ̀kẹ́-ẹṣin púpọ̀ ń súré lọ ogun. 10 Wọ́n ni ìrù àti oró àkéekèe, àti ìrù wọn ni agbára wọn láti pa ènìyàn lára fún oṣù márùn-ún. 11 Wọ́n angẹli ̀gbun náà ọba lórí wọn, orúkọ rẹ̀ èdè Heberu Abaddoni, àti ni èdè Giriki orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Apollioni (èyí ni Apanirun).

12 Ègbé kan kọjá, kíyèsi i, ègbé méjì ń bọ̀ síbẹ̀ lẹ́yìn èyí.

13 9.13: Ek 30.1-3. Angẹli kẹfà si fọn ìpè rẹ̀, mo gbọ́ ohùn kan láti ibi ìwo mẹ́rin pẹpẹ wúrà , ń bẹ níwájú Ọlọ́run. 14 Òun fún angẹli kẹfà náà o ni ìpè náà , "àwọn angẹli mẹ́rin náà sílẹ̀ a lẹ́bàá odò ńlá Eufurate!" 15 A àwọn angẹli mẹ́rin náà sílẹ̀, a ti pèsè tẹ́lẹ̀ fún wákàtí náà, àti ọjọ́ náà, àti oṣù náà, àti ọdún náà, láti pa ìdámẹ́ta ènìyàn. 16 Iye ogún àwọn ẹlẹ́ṣin jẹ́ àádọ́ta ̀kẹ́ lọ́igba, mo gbọ́ iye wọn.

17 Báyìí ni mo àwọn ẹṣin náà ojúran, àti àwọn o gùn wọ́n, wọ́n ni ìgbàyà aláwọ̀ iná, àti ti jakinti, àti ti sulfuru, orí àwọn ẹṣin náà dàbí orí àwọn kìnnìún; àti láti ẹnu wọn ni iná, àti èéfín, àti sulfuru ń jáde. 18 Nípa ìyọnu mẹ́ta wọ̀nyí ni a pa ìdámẹ́ta ènìyàn, nípa iná, àti nípa èéfín, àti nípa sulfuru o ń ẹnu wọn jáde. 19 Nítorí agbára àwọn ẹṣin náà ń bẹ ẹnu wọn àti ìrù wọn: nítorí ìrù wọn dàbí ejò, wọn orí, àwọn wọ̀nyí ni wọn fi ń pa ni lára.

20 9.20: Isa 17.8; Sm 115.4-7; 135.15-17. Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn ìyókù a ti ipa ìyọnu wọ̀nyí pa, ronúpìwàdà iṣẹ́ ọwọ́ wọn, wọn ṣe sin àwọn ̀èṣù àti ère wúrà, àti ti fàdákà, àti ti idẹ, àti òkúta, àti ti igi mọ́: àwọn ríran, tàbí wọn gbọ́rọ̀, tàbí wọn rìn. 21 Bẹ́̀ ni wọn ronúpìwàdà ìwà ìpànìyàn wọn, tàbí oṣó wọn tàbí àgbèrè wọn, tàbí olè wọn.

Veja também