Publicidade

Atos 1

A Jesu lọ ̀run

1 Nínú ìwé mi ìṣáájú, Teofilu, ni mo ti kọ ti ohun gbogbo Jesu bẹ̀rẹ̀ ṣe àti kọ́ 2 títí ó fi di ọjọ́ a gbà á lọ sókè ̀run, lẹ́yìn ó ti ti ipa ̀Mímọ́ pàṣẹ fún àwọn aposteli ó yàn. 3 Lẹ́yìn ìjìyà rẹ̀, ó fi ara rẹ̀ hàn fún wọn àti ̀pọ̀lọpọ̀ ̀ó dájú òun láààyè. Ó fi ara hàn wọ́n fún ogójì ọjọ́, ó sọ̀rọ̀ nípa ìjọba Ọlọ́run. 4 àkókò kan ó ti ń jẹun pẹ̀wọn, ó pàṣẹ yìí fún wọn, "ṣe kúrò Jerusalẹmu, ṣùgbọ́n dúró de ìlérí Baba mi ṣe ìlérí, èyí ̀yin gbọ́ lẹ́nu mi. 5 Nítorí Johanu fi omi bamitiisi yín, ṣùgbọ́n ọjọ́ díẹ̀ i, a o fi ̀Mímọ́ bamitiisi yín."

6 Nítorí náà, nígbà wọ́n péjọpọ̀, wọn bi í léèrè , "Olúwa, láti ìgbà lọ ìwọ yóò ha ìjọba padà fún Israẹli ?"

7 Ó fún wọn , "í ṣe tiyín ni láti mọ àkókò tàbí ìgbà Baba ti yàn nípa àṣẹ òun tìkára rẹ̀. 8 Ṣùgbọ́n ̀yin yóò gba agbára, nígbà ̀Mímọ́ e yín; ̀yin yóò máa ṣe ẹlẹ́rìí mi ni Jerusalẹmu, àti gbogbo Judea, àti Samaria, àti títí òpin ilẹ̀ ayé."

9 Nígbà ó nǹkan wọ̀nyí, a gbà á sókè lójú wọn; ìkùùkuu àwọsánmọ̀ gbà á kúrò lójú wọn.

10 wọ́n ti tẹjúmọ́ ojú ̀run ó ti ń lọ sókè, lójijì, àwọn ọkùnrin méjì ó wọ aṣọ funfun dúró létí ̀dọ̀ wọn. 11 Wọ́n , "̀yin ara Galili, èéṣe ̀yin fi dúró ̀ ń wo ojú ̀run? Jesu yìí, a gbà sókè ̀run kúrò lọ́wọ́ yín, yóò padà bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ti ó ń lọ ̀run."

A yan Mattia Rọ́Judasi

12 Lẹ́yìn náà ni wọ́n padà Jerusalẹmu láti orí òkè ti a ń ni olifi, ó ìwọ̀n ìrìn ọjọ́ ìsinmi kan. 13 Nígbà wọn wọlé, wọn lọ iyàrá òkè, níbi wọ́n ń gbé. Àwọn níbẹ̀ ni:

Peteru, Jakọbu, Johanu àti Anderu;

Filipi àti Tomasi;

Bartolomeu àti Matiu;

Jakọbu ọmọ Alfeu, Simoni Sealoti, àti Judasi arákùnrin Jakọbu.

14 Gbogbo àwọn wọ̀nyí pẹ̀àwọn obìnrin àti Maria ìyá Jesu àti àwọn arákùnrin rẹ̀ fi ọkàn kan dúró láti máa gbàdúrà.

15 ọjọ́ wọ̀nyí ni Peteru dìde dúró láàrín àwọn ọmọ-ẹ̀yìn (iye àwọn ènìyàn wọ̀nyí jẹ́ ọgọ́) 16 ó , "̀yin ará, ìwé mímọ́ ṣe ó ṣẹ, èyí ̀Mímọ́ ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu Dafidi nípa Judasi, ó ṣe atọ́fún àwọn ó Jesu. 17 Nítorí ̀kan nínú wa ni òun ń ṣe tẹ́lẹ̀, òun ìpín nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ yìí."

18 (Judasi fi èrè àìṣòótọ́ rẹ̀ ra ilẹ̀ kan; nígbà ó ṣubú ni ògèdèǹgbé, ó bẹ́ agbede-méjì, gbogbo ìfun rẹ̀ jáde. 19 Ó si di mọ̀ fún gbogbo àwọn ti ń gbé Jerusalẹmu; nítorí náà ni wọ́n fi ń ilẹ̀ náà ni Alkedama èdè wọn, èyí ni, Ilẹ̀ ̀jẹ̀.)

20 Peteru , "Nítorí a ti kọ ́ nípa rẹ̀ nínú Ìwé Saamu ,

" Jẹ́ ki ibùgbé rẹ̀ di ahoro,

ẹnikẹ́ni ṣe gbé inú rẹ̀,’

àti,

" Ipò rẹ̀ ni ẹlòmíràn ó gbà.

21 Nítorí náà, ó di dandan láti yan ̀kan nínú àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ti ń wa rìn ni gbogbo àkókò Jesu Olúwa ń wọlé, ó jáde láàrín wa. 22 Bẹ́̀ láti ìgbà bamitiisi Johanu títí ó fi di ọjọ́ náà ti a gbe é lọ sókè kúrò lọ́dọ̀ wa. Ó yẹ ̀kan nínú àwọn wọ̀nyí ṣe ẹlẹ́rìí àjíǹde rẹ̀ pẹ̀wa."

23 Wọn yan àwọn méjì, Josẹfu a ń Barsaba (ẹni a sọ àpèlé rẹ̀ ni Justu) àti Mattia. 24 Wọn gbàdúrà, wọn , "Olúwa, ìwọ mọ ọkàn gbogbo ènìyàn, fihàn nínú àwọn méjì yìí, èwo ni ìwọ yàn 25 ó gba ipò nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ aposteli yìí, èyí Judasi kúrò nínú rẹ̀, ki òun ó lọ ipò ti ara rẹ̀." 26 Wọ́n dìbò fún wọn; ìbò Mattia; a á mọ́ àwọn aposteli mọ́kànlá.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-