Publicidade

Atos 13

1 Àwọn wòlíì àti àwọn olùkọ́ni ń bẹ nínú ìjọ ti ó ni Antioku; Barnaba àti Simeoni a ń ni Nigeri, àti Lukiu ará Kirene, àti Manaeni (ẹni a tọ́ pọ̀ pẹ̀Herodu tetrarki) àti Saulu. 2 wọn ti ń jọ́sìn fún Olúwa, wọ́n ń gbààwẹ̀, ̀Mímọ́ , "ya Barnaba àti Saulu sọ́tọ̀ fún mi fún iṣẹ́ ti mo ti wọ́n !" 3 Nígbà wọ́n ti gbààwẹ̀, wọn ti gbàdúrà, wọ́n gbé ọwọ́ wọn, wọ́n rán wọn lọ.

Saipurọsi

4 Ǹjẹ́ ̀Mímọ́ ti rán àwọn méjèèjì lọ, wọ́n sọ̀kalẹ̀ lọ Seleusia; láti ibẹ̀ wọ́n wọ ọkọ̀ ojú omi lọ Saipurọsi. 5 Nígbà ti wọ́n ni Salami, wọ́n ń wàásù ̀rọ̀ Ọlọ́run Sinagọgu àwọn Júù. Johanu náà pẹ̀wọn láti ràn wọ́n lọ́wọ́ fún ìránṣẹ́ wọn.

6 Nígbà wọ́n la gbogbo erékùṣù Pafosi, wọ́n ọkùnrin oṣó àti wòlíì èké kan ti i ṣe Júù, orúkọ ẹni ti ó ń jẹ́ Bar-Jesu. 7 Ó lọ́dọ̀ Segiu Paulusi baálẹ̀ ìlú náà í ṣe amòye ènìyàn. Òun náà ni ó ránṣẹ́ pe Barnaba àti Saulu, nítorí ó fẹ́ gbọ́ ̀rọ̀ Ọlọ́run. 8 Ṣùgbọ́n Elimu oṣó (nítorí bẹ́̀ ni ìtumọ̀ orúkọ rẹ̀) takò wọ́n, ó ń fẹ́ pa baálẹ̀ ni ọkàn kúrò ni ìgbàgbọ́. 9 Ṣùgbọ́n Saulu ti a ń ni Paulu, ó kún fún ̀Mímọ́, ó tẹjúmọ́ Elimu, ó , 10 "Ìwọ ti ó kún fún àrékérekè gbogbo, àti fún ìwà ìkà gbogbo, ìwọ ọmọ èṣù, ìwọ ̀ohun gbogbo, ìwọ yóò ha dẹ́kun láti máa ̀òtítọ́ Olúwa po? 11 Ǹjẹ́ nísinsin yìí ó, ọwọ́ Olúwa ń bẹ lára rẹ̀, ìwọ ó fọjú ìwọ yóò oòrùn à kan!"

Lójúkan náà, ìkùùkuu àti òkùnkùn ó; ó ń ènìyàn kiri láti fa òun lọ́wọ́ lọ. 12 Nígbà baálẹ̀ ohun ó ṣe, ó gbàgbọ́, ẹnu á ̀kọ́ Olúwa.

Pisidia ti Antioku

13 Nígbà Paulu àti àwọn ó pẹ̀rẹ̀ si ṣíkọ̀ ni Pafosi wọ́n Perga ni Pamfilia: Johanu fi wọ́n sílẹ̀, ó padà lọ Jerusalẹmu. 14 Nígbà ti wọ́n Perga kọjá, wọ́n Pisidia Antioku. Wọ́n wọ inú Sinagọgu ọjọ́ ìsinmi, wọ́n jókòó. 15 Lẹ́yìn kíka ìwé òfin àti ìwé àwọn wòlíì, àwọn olórí Sinagọgu ránṣẹ́ wọn, , "Ará, ̀yin ni ̀rọ̀ ìyànjú kan fún àwọn ènìyàn, sọ ́!"

16 Paulu dìde dúró, ó juwọ́ wọn, ó , "̀yin Israẹli, àti ̀yin ti ó bẹ̀Ọlọ́run, fi etí sílẹ̀ mi! 17 Ọlọ́run àwọn ènìyàn Israẹli yìí yan àwọn baba wa, ó gbé àwọn ènìyàn náà lékè, nígbà wọ́n ṣe àtìpó ilẹ̀ Ejibiti, pẹ̀agbára ńlá ni ó fi wọn jáde kúrò nínú rẹ̀, 18 ìwọ̀n ìgbà ogójì ọdún ni ó fi sùúrù fún ìwà wọn ijù, 19 nígbà ó ti run orílẹ̀-èdè méje ni ilẹ̀ Kenaani, ó fi ilẹ̀ wọn fún àwọn ènìyàn rẹ̀ ni ìní. 20 Gbogbo èyí ṣẹlẹ̀ fún ìwọ̀n àádọ́ta irinwó (450) ọdún.

"Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí ni Ọlọ́run fi onídàájọ́ fún wọn, títí ó fi di ìgbà Samuẹli wòlíì. 21 Lẹ́yìn náà ni wọ́n béèrè ọba; Ọlọ́run fún wọn Saulu ọmọ Kiṣi, ọkùnrin kan nínú ̀Benjamini, fún ogójì ọdún. 22 Nígbà ti ó Saulu kúrò, ó gbé Dafidi dìde ọba fún wọn, ẹni ó jẹ́rìí rẹ̀ , Mo Dafidi ọmọ Jese ẹni ọkàn mi, ti yóò ṣe gbogbo ìfẹ́ mi.

23 "Láti inú irú-ọmọ ọkùnrin yìí ni Ọlọ́run ti gbé Jesu Olùgbàlà dìde fún Israẹli gẹ́gẹ́ ìlérí. 24 Ṣáájú wíwá Jesu ni Johanu ti wàásù bamitiisi ìrònúpìwàdà fún gbogbo ènìyàn Israẹli. 25 Johanu ti ńlá ipa tirẹ̀ , ó ni, Ta ni ̀yin ṣe èmi jẹ́? Èmi í ṣe òun. Ṣùgbọ́n kíyèsi í, ẹnìkan ń bọ̀ lẹ́yìn mi, bàtà ẹsẹ̀ ẹni èmi .

26 "Ará, ̀yin ọmọ ìran Abrahamu, àti ̀yin ti ó bẹ̀Ọlọ́run, àwa ni a rán ̀rọ̀ ìgbàlà yìí . 27 Nítorí àwọn ń gbé Jerusalẹmu, àti àwọn olórí wọn, nítorí tiwọn mọ̀ Jesu, wọn òye ̀rọ̀ àwọn wòlíì, a ń ọjọọjọ́ ìsinmi fún wọn, wọn, wọ́n ̀rọ̀ àwọn wòlíì yìí ṣẹ nípa dídá a lẹ́bi. 28 Àti wọn tilẹ̀ ti ̀ràn ikú i, síbẹ̀ wọn rọ Pilatu láti pa á. 29 wọ́n ti nǹkan gbogbo ṣẹ ti a kọ̀nítorí rẹ̀, wọn sọ̀ ́ kalẹ̀ kúrò lórí igi, wọ́n tẹ́ ibojì. 30 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run i dìde kúrò nínú òkú, 31 o farahàn lọ́jọ́ púpọ̀ fún àwọn ó a gòkè láti Galili Jerusalẹmu, àwọn í ṣe ẹlẹ́rìí rẹ̀ nísinsin yìí fún àwọn ènìyàn.

32 "Àwa ìyìnrere fún yín , ìlérí èyí Ọlọ́run ti ṣe fún àwọn baba wa, 33 èyí ni Ọlọ́run ti ṣẹ fún àwa ọmọ wọn, nípa gbígbé Jesu dìde, a ti kọ̀rẹ̀ nínú Saamu kejì ,

" Ìwọ ni Ọmọ mi;

lónìí ni mo .

34 Àti ni Ọlọ́run i dìde kúrò nínú òkú, ẹni yóò tún padà ìbàjẹ́ mọ́, ó báyìí :

" Èmi ó fún yín ̀rẹ́ mímọ́ Dafidi, ó dájú.

35 Nítorí ó nínú Saamu mìíràn pẹ̀,

" Ìwọ yóò jẹ́ Ẹni Mímọ́ rẹ ìdíbàjẹ́.’

36 "Nítorí lẹ́yìn ìgbà ti Dafidi ti sin ìran rẹ tan nípa ìfẹ́ Ọlọ́run, ó sùn, a tẹ́ ti àwọn baba rẹ̀, ara rẹ̀ ìdíbàjẹ́. 37 Ṣùgbọ́n ẹni Ọlọ́run dìde ìdíbàjẹ́.

38 "Ǹjẹ́ ó yín, ará nípasẹ̀ Jesu yìí ni a ń wàásù ìdáríjì ̀ṣẹ̀ fún yín. 39 Nípa rẹ̀ ni a ń olúkúlùkù ẹni ó gbàgbọ́ láre kúrò nínú ohun gbogbo, a yín láre rẹ̀ nínú òfin Mose. 40 Nítorí náà, kíyèsára, èyí a ti sọ nínú ìwé àwọn wòlíì ṣe yín :

41 " ó, ̀yin ẹlẹ́gàn,

ẹnu yín, a fẹ́ yín ;

nítorí èmi ó ṣe ohun kan ọjọ́ yín,

̀yin jẹ́ gbàgbọ́,

a tilẹ̀ sọ fún yin.’ "

42 Paulu àti Barnaba ti ń jáde láti inú Sinagọgu, wọ́n bẹ̀bẹ̀ a sọ̀rọ̀ wọ̀nyí i fún wọn lọ́jọ́ ìsinmi ń bọ̀. 43 Nígbà wọn jáde nínú Sinagọgu, ̀pọ̀ nínú àwọn Júù àti nínú àwọn olùfọkànsìn aláwọ̀ṣe Júù tẹ̀Paulu àti Barnaba, àwọn ẹni ó wọn sọ̀rọ̀ wọ́n rọ̀ wọ́n láti dúró nínú oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run.

44 ọjọ́ ìsinmi kejì, gbogbo ìlú fẹ́rẹ̀ péjọ tan láti gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa. 45 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn Júù ̀pọ̀ ènìyàn náà, wọ́n kún fún owú, wọ́n ń sọ̀rọ̀-òdì ohun ti Paulu ń sọ.

46 Paulu àti Barnaba wọn lóhùn láìbẹ̀, "̀yin ni ó tọ́ ki a kọ́kọ́ sọ ̀rọ̀ Ọlọ́run fún yín, ṣùgbọ́n ̀yin ti ta á , ka ara yín aláìyẹ fún ìyè àìnípẹ̀kun, ó, àwa yípadà sọ́dọ̀ àwọn aláìkọlà. 47 Bẹ́̀ ni Olúwa ṣa ti pàṣẹ fún wa :

" Mo ti gbé kalẹ̀ láti tan ìmọ́lẹ̀ fún àwọn aláìkọlà,

ìwọ ìgbàlà títí òpin ayé.’ "

48 Nígbà àwọn aláìkọlà gbọ́ èyí, wọ́n yín ̀rọ̀ Ọlọ́run lógo: gbogbo àwọn a yàn ìyè àìnípẹ̀kun gbàgbọ́.

49 A tan ̀rọ̀ Olúwa gbogbo agbègbè náà. 50 Ṣùgbọ́n àwọn Júù àwọn obìnrin olùfọkànsìn àti ọlọ́sókè àti àwọn àgbà ìlú náà, wọ́n gbé inúnibíni dìde Paulu àti Barnaba, wọ́n le wọn kúrò ni agbègbè wọn. 51 Ṣùgbọ́n wọ́n gbọn eruku ẹsẹ̀ wọn wọn, wọn Ikoniomu. 52 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn si kún fún ayọ̀ àti fún ̀Mímọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-