Pular para o conteúdo
Publicidade

Atos 2

Peteru wàásù ̀pọ̀ ènìyàn

14 Nígbà náà ni Peteru dìde dúró pẹ̀àwọn mọ́kànlá yòókù, ó gbé ohùn rẹ̀ sókè, ó fún wọn , "̀yin Júù ènìyàn mi àti gbogbo ̀yin ń gbé Jerusalẹmu, jẹ́ èyí ó yin; fetísí ̀rọ̀ mi. 15 Àwọn wọ̀nyí mu ọtí , ̀yin ó; wákàtí kẹta ọjọ́ à ni èyí. 16 Bẹ́̀ kọ́, èyí ni ̀rọ̀ ti a ti sọ láti ẹnu wòlíì Joẹli :

17 2.17-21: Jl 2.28-32. "Ọlọ́run , ìkẹyìn ọjọ́,

Èmi yóò nínú ̀jáde sára ènìyàn gbogbo,

àwọn ọmọ yín ọkùnrin àti àwọn ọmọ yín obìnrin yóò máa sọtẹ́lẹ̀

àwọn ̀dọ́mọkùnrin yín yóò máa ríran,

àwọn arúgbó yín yóò máa àlá,

18 àti sára àwọn ọmọ ̀dọ̀ mi ọkùnrin àti sára àwọn ọmọ ̀dọ̀ mi obìnrin,

ni Èmi yóò nínú ̀mi jáde ni ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì:

wọn yóò máa sọtẹ́lẹ̀.

19 Èmi yóò fi iṣẹ́ ìyanu hàn lójú ̀run,

àti àwọn àmì nísàlẹ̀ ilẹ̀;

̀jẹ̀ àti iná àti rírú èéfín;

20 A ó sọ oòrùn di òkùnkùn,

àti òṣùpá di ̀jẹ̀,

ọjọ́ ńlá àti ọjọ́ ológo Olúwa .

21 Yóò ṣe, ẹnikẹ́ni ó pe

orúkọ Olúwa ni a ó gbàlà.

22 "̀yin ènìyàn Israẹli, gbọ́ ̀rọ̀ wọ̀nyí; Jesu Nasareti, ọkùnrin a mọ̀ láti ̀dọ̀ Ọlọ́run nípa iṣẹ́ agbára àti ìyanu, àti àmì ti Ọlọ́run ti ọwọ́ rẹ̀ ṣe láàrín yín, ̀yin tìkára yín ti mọ̀ pẹ̀. 23 Ẹni a ti fi yín lọ́wọ́ nípa ìpinnu ìmọ̀ àti ìmọ̀tẹ́lẹ̀ Ọlọ́run; àti ̀yin pẹ̀, a pa á pẹ̀ìrànlọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú, a kàn mọ́ àgbélébùú. 24 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run dìde kúrò nínú òkú, gbà á kúrò nínú ìrora ikú, nítorí ṣe é ṣe fún ikú láti dìímú. 25 2.25-28: Sm 16.8-11.Dafidi nípa tirẹ̀ :

" Mo Olúwa nígbà gbogbo níwájú ,

nítorí ó ń bẹ lọ́wọ́ ̀tún mi,

a ó ṣí mi ipò.

26 Nítorí náà inú mi dùn, ahọ́n mi yọ̀,

pẹ̀lúpẹ̀ara mi yóò sinmi ìrètí.

27 Nítorí ìwọ yóò fi ọkàn mi sílẹ̀ ni isà òkú,

bẹ́̀ ni ìwọ yóò jẹ́ Ẹni Mímọ́ rẹ ìdíbàjẹ́.

28 Ìwọ mi mọ ̀ìyè,

ìwọ yóò mi kún fún ayọ̀ ni iwájú rẹ.

29 "Ará, èmí sọ fún yín pẹ̀ìgboyà Dafidi baba ńlá , a sin ín, ibojì rẹ̀ ń bẹ lọ́dọ̀ wa títí di òní yìí. 30 2.30: Sm 132.11.Ṣùgbọ́n ó jẹ́ wòlíì, àti ó mọ́ , Ọlọ́run ti ṣe ìlérí fún òun nínú ìbúra nínú irú-ọmọ inú rẹ̀, òun yóò ̀kan jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀. 31 2.31: Sm 16.10.èyí tẹ́lẹ̀, ó sọ ti àjíǹde Kristi, a fi ọkàn rẹ̀ sílẹ̀ ni isà òkú, bẹ́̀ ni ara rẹ̀ ìdíbàjẹ́. 32 Jesu náà yìí ni Ọlọ́run ti dìde ìyè, àwa pẹ̀jẹ́rìí èyí. 33 A ti gbéga ọwọ́ ̀tún Ọlọ́run, ó ti gba ìlérí ̀Mímọ́ láti ̀dọ̀ Baba, ó tu èyí ̀yin àti gbọ́ nísinsin yìí síta. 34 2.34-35: Sm 110.1.Nítorí Dafidi gòkè lọ ̀run ṣùgbọ́n òun tìkára rẹ̀ ,

" Olúwa sọ fún Olúwa mi :

"Jókòó ọwọ́ ̀tún mi

35 títí èmi yóò fi sọ àwọn ̀rẹ

àpótí ìtìsẹ̀ fún ẹsẹ̀ rẹ." 

36 "Ǹjẹ́ gbogbo ilé Israẹli mọ̀ dájúdájú , Ọlọ́run ti fi Jesu náà, ti ̀yin kàn mọ́ àgbélébùú, ṣe Olúwa àti Kristi."

37 Nígbà wọ́n gbọ́, ọkàn wọn gbọgbẹ́, wọn fún Peteru àti àwọn aposteli yòókù , "Ará, kín ni àwa yóò ṣe?"

38 Peteru fún wọn , "ronúpìwàdà, a bamitiisi olúkúlùkù yín orúkọ Jesu Kristi fún ìdáríjì ̀ṣẹ̀ yín. ̀yin yóò gba ̀bùn ̀Mímọ́. 39 2.39: Isa 57.19; Jl 2.32.Nítorí fún yín ni ìlérí náà, àti fún àwọn ọmọ yín, àti fún gbogbo àwọn ó jìnnà réré, àní gbogbo àwọn Olúwa Ọlọ́run wa yóò ."

40 Pẹ̀̀rọ̀ púpọ̀ mìíràn ni ó fi ń kìlọ̀ ó ń fi ń rọ̀ wọ́n , "gba ara yín lọ́wọ́ ìran àrékérekè yìí." 41 Nítorí náà àwọn ó fi ayọ̀ gba ̀rọ̀ rẹ̀ a bamitiisi wọn, lọ́jọ́ náà a ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) ọkàn kún wọn.

Veja também